< Psalmów 61 >

1 Przedniejszemu śpiewakowi na Neginot pieśń Dawidowa. Wysłuchaj, o Boże! wołanie moje, miej pozór na modlitwę moję.
Fún adarí orin. Ohun èlò orin olókùn. Ti Dafidi. Gbọ́ ẹkún mi, Ọlọ́run; tẹ́tí sí àdúrà mi.
2 Od końca ziemi wołam do ciebie w zatrwożeniu serca mego; wprowadź mię na skałę, która jest wywyżą nad mię.
Láti òpin ayé wá ni èmi yóò pè ọ́, mo pè nígbà àyà mi ń ṣàárẹ̀; mú mi lọ sí ibi àpáta tí ó ga jù mí lọ.
3 Albowiemeś ty był ucieczką moją, i basztą mocną przed twarzą nieprzyjaciela.
Nítorí ìwọ ti jẹ́ ibi ààbò mi, ilé ìṣọ́ agbára àwọn ọ̀tá.
4 Będę mieszkał w przybytku twoim na wieki, schraniając się pod zasłonę skrzydeł twoich. (Sela)
Mo ń lépa láti máa gbé nínú àgọ́ rẹ títí láé kí n sì rí ààbò níbi ìyẹ́ apá rẹ.
5 Albowiemeś ty, Boże! wysłuchał żądości moje; tyś dał dziedzictwo tym, którzy się boją imienia twego.
Nítorí ìwọ ti gbọ́ àwọn ẹ̀jẹ́ mi, Ọlọ́run; Ìwọ ti fún mi ní ogún àwọn tí ó bẹ̀rù orúkọ rẹ.
6 Dni do dni królewskich przydaj; niech będą lata jego od narodu do narodu.
Jẹ́ kí ẹ̀mí ọba kí ó gùn, ọdún rẹ̀ fún ìrandíran.
7 Niech mieszka na wieki przed obliczem Bożem; zgotuj miłosierdzie i prawdę, niech go strzegą.
Kí ó máa jẹ ọba níwájú Ọlọ́run títí láé; pèsè àánú àti òtítọ́ rẹ tí yóò máa ṣe ìtọ́jú rẹ.
8 Tak będę śpiewał imieniowi twemu na wieki, a śluby moje oddawać będę na każdy dzień.
Nígbà náà ni èmi ó máa kọrin ìyìn sí orúkọ rẹ títí láé kí n san ẹ̀jẹ́ mi ní ojoojúmọ́.

< Psalmów 61 >