< II Samuela 20 >

1 Tedy się tam pojawił mąż niepobożny, którego zwano Seba, syn Bichry, mąż Jemini. Ten zatrąbił w trąbę, i rzekł: Nie mamy my działu w Dawidzie, ani mamy dziedzictwa w synu Isajego; wróć się każdy do namiotów swoich, o Izraelu!
Ọkùnrin Beliali kan sì ń bẹ níbẹ̀ orúkọ rẹ̀ sì ń jẹ́ Ṣeba ọmọ Bikri ará Benjamini; ó sì fún ìpè ó sì wí pé, “Àwa kò ní ipa nínú Dafidi, bẹ́ẹ̀ ni àwa kò ni ìní nínú ọmọ Jese! Kí olúkúlùkù ọkùnrin lọ sí àgọ́ rẹ̀, ẹ̀yin Israẹli!”
2 A tak odstąpili wszyscy mężowie Izraelscy od Dawida za Sebą, synem Bichry; ale mężowie Judzcy trzymali się króla swego, od Jordanu aż do Jeruzalemu.
Gbogbo àwọn ọkùnrin Israẹli sì lọ kúrò lẹ́yìn Dafidi, wọ́n sì ń tọ́ Ṣeba ọmọ Bikri lẹ́yìn, ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin Juda sì fi ara mọ́ ọba wọn láti odò Jordani wá títí ó fi dé Jerusalẹmu.
3 I przyszedł Dawid do domu swego w Jeruzalemie; a wziąwszy król dziesięć niewiast założnic, które był zostawił, aby strzegły domu, oddał je pod straż, i żywił je, ale do nich nie wchodził; i były pod strażą aż do dnia śmierci swojej, we wdowim stanie.
Dafidi sì wà ní ilé rẹ̀ ní Jerusalẹmu; ọba sì mú àwọn obìnrin mẹ́wàá tí í ṣe àlè rẹ̀, àwọn tí ó ti fi sílẹ̀ láti máa ṣọ́ ilé, Ó sì há wọn mọ́ ilé, ó sì ń bọ́ wọn, ṣùgbọ́n kò sì tún wọlé tọ̀ wọ́n mọ́. A sì sé wọn mọ́ títí di ọjọ́ ikú wọn, wọ́n sì wà bí opó.
4 Potem rzekł król do Amazy: Zbierz mi męże Judzkie za trzy dni; ty się też tu staw.
Ọba sì wí fún Amasa pé, “Pe àwọn ọkùnrin Juda fún mi ní ìwọ̀n ọjọ́ mẹ́ta òní, kí ìwọ náà kí o sì wà níhìn-ín yìí.”
5 A tak poszedł Amaza, aby zebrał lud Judzki; lecz się zabawił nad czas naznaczony, który mu był naznaczył.
Amasa sì lọ láti pe àwọn ọkùnrin Juda; ṣùgbọ́n ó sì dúró pẹ́ ju àkókò tí a fi fún un.
6 I rzekł Dawid do Abisajego: Teraz gorzej nam uczyni Seba, syn Bichry, niż Absalom; przetoż ty weźmij sługi pana twego, a goń go, by snać nie znalazł sobie miast obronnych, i nie uszedł z oczu naszych.
Dafidi sì wí fún Abiṣai pé, “Nísinsin yìí Ṣeba ọmọ Bikri yóò ṣe wá ní ibi ju ti Absalomu lọ; ìwọ mú àwọn ìránṣẹ́ olúwa rẹ, kí o sì lépa rẹ̀, kí ó má ba à rí ìlú olódi wọ̀, kí ó sì bọ́ lọ́wọ́ wa.”
7 Tedy wyszli z nim mężowie Joabowi, i Chertczycy i Feletczycy, i wszystko rycerstwo, a wyszli z Jeruzalemu w pogoń za Sebą, synem Bichry.
Àwọn ọmọkùnrin Joabu sì jáde tọ̀ ọ́ lọ, àti àwọn Kereti, àti àwọn Peleti, àti gbogbo àwọn ọkùnrin alágbára, wọ́n sì ti Jerusalẹmu jáde lọ, láti lépa Ṣeba ọmọ Bikri.
8 A gdy byli u wielkiego kamienia, który jest w Gabaon, tedy im Amaza zabieżał. A Joab miał przepasaną szatę swą, w której chodził, a na niej pas z mieczem przypasany do biódr swoich w pochwach swych, którego snadnie mógł dobyć, i zaś schować.
Nígbà tí wọ́n dé ibi òkúta ńlá tí ó wà ní Gibeoni, Amasa sì ṣáájú wọn, Joabu sì di àmùrè sí agbádá rẹ̀ tí ó wọ̀, ó sì sán idà rẹ̀ mọ́ ìdí, nínú àkọ̀ rẹ̀, bí ó sì ti ń lọ, ó yọ́ jáde.
9 I rzekł Joab do Amazy: Jakoż się masz, bracie mój? I ujął ręką prawą Joab Amazę za brodę, jakoby go całować miał.
Joabu sì bi Amasa léèrè pé, “Àlàáfíà ha kọ́ ni bí, ìwọ arákùnrin mi?” Joabu sì na ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀, di Amasa ní irùngbọ̀n mú láti fi ẹnu kò ó lẹ́nu.
10 Ale Amaza nie postrzegł miecza, który był w ręce Joabowej: i przebił go nim pod piąte żebro, i wylał trzewa jego na ziemię, a tak za jadną raną umarł. A Joab i Abisaj, brat jego, szli w pogoń za Sebą, synem Bichry.
Ṣùgbọ́n Amasa kò sì kíyèsi idà tí ń bẹ lọ́wọ́ Joabu, bẹ́ẹ̀ ni òun sì fi gún un ní ikùn, ìfun rẹ̀ sì tú dà sílẹ̀, òun kò sì tún gún un mọ́, Amasa sì kú. Joabu àti Abiṣai arákùnrin rẹ̀ sì lépa Ṣeba ọmọ Bikri.
11 Tedy stanął jeden nad nim z sług Joabowych, i rzekł: Ktokolwiek jest życzliwy Joabowi, a ktokolwiek trzyma z Dawidem, niech idzie za Joabem.
Ọ̀kan nínú àwọn ọ̀dọ́mọdékùnrin tí ó wà lọ́dọ̀ Joabu sì dúró tì Amasa, ó sì wí pé, “Ta ni ẹni tí ó fẹ́ràn Joabu? Ta ni ó sì ń ṣe ti Dafidi, kí ó máa tọ Joabu lẹ́yìn.”
12 Lecz Amaza walał się w krwi w pośród drogi. A widząc on mąż, iż się zastanawiał wszystek lud nad nim, zwlekł Amazę z drogi na pole, i przyrzucił go szatą, gdyż widział, że ktokolwiek szedł mimo niego, zastanawiał się.
Amasa sì ń yíràá nínú ẹ̀jẹ̀ láàrín ọ̀nà. Ọkùnrin náà sì rí i pé gbogbo ènìyàn sì dúró tì í, ó sì gbé Amasa kúrò lójú ọ̀nà lọ sínú igbó, ó sì fi aṣọ bò ó, nígbà tí ó rí i pé ẹnikẹ́ni tí ó bá dé ọ̀dọ̀ rẹ̀, á dúró.
13 A gdy był zwleczony z drogi, bieżał każdy mąż za Joabem, goniąc Sebę, syna Bichry.
Nígbà tí ó sì gbé Amasa kúrò lójú ọ̀nà gbogbo ènìyàn sì tọ Joabu lẹ́yìn láti lépa Ṣeba ọmọ Bikri.
14 Który już był przeszedł przez wszystkie pokolenia Izraelskie, aż do Abel i Betmaacha, ze wszystkimi Berymczykami, którzy się też byli zebrali, a szli za nim.
Ṣeba kọjá nínú gbogbo ẹ̀yà Israẹli sí Abeli-Beti-Maaka, àti gbogbo àwọn ará Beri; wọ́n sì kó ara wọn jọ, wọ́n sì tọ̀ ọ́ lẹ́yìn pẹ̀lú.
15 A gdy się tam ściągnęli, oblegli go w Abeli Betmaacha, i usypali szańce przeciw miastu, tak iż stali przed murem, a wszystek lud, który był z Joabem, usiłował obalić mury.
Wọ́n wá, wọ́n sì dó tì Ṣeba ní Abeli-Beti-Maaka, wọ́n sì mọ odi ti ìlú náà, odi náà sì dúró ti odi ìlú náà, gbogbo ènìyàn tí ń bẹ lọ́dọ̀ Joabu sì ń gbìyànjú láti wó ògiri náà lulẹ̀.
16 Wtem zawołała z miasta niektóra niewiasta mądra: Słuchajcie, słuchajcie! rzeczcie proszę do Joaba: Przystąp sam, a rozmówię się z tobą.
Obìnrin ọlọ́gbọ́n kan sì kígbe sókè láti ìlú náà wá pé, “Fetísílẹ̀! Fetísílẹ̀! Èmi bẹ̀ yín, ẹ sọ fún Joabu pé, ‘Súnmọ́ ìhín yìí èmi ó sì bá a sọ̀rọ̀.’”
17 Który gdy do niej przystąpił, rzekła mu ona niewiasta: Tyżeś jest Joab? I odpowiedział: Jestem. Tedy mu rzekła: Słuchaj słów służebnicy twojej; i odpowiedział: Słucham.
Nígbà tí òun sì súnmọ́ ọ̀dọ̀ rẹ̀, obìnrin náà sì wí pé, “Ìwọ ni Joabu bí?” Òun sì dáhùn wí pé, “Èmi náà ni.” Obìnrin náà sì wí fún un pé, “Gbọ́ ọ̀rọ̀ ìránṣẹ́bìnrin rẹ.” Òun sì dáhùn wí pé, “Èmi ń gbọ́.”
18 Przetoż rzekła, mówiąc: Powiadano przedtem, mówiąc: Koniecznie pytać się będą w Abelu, a tak się wszystko sprawi.
Ó sì sọ̀rọ̀ wí pé, “Wọ́n ti ń wí ṣáájú pé, ‘Gba ìdáhùn rẹ ní Abeli,’ bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì parí ọ̀ràn náà.
19 Jam jest jedno miasto z spokojnych i wiernych w Izraelu, a ty szukasz, abyś zatracił miasto i matkę w Izraelu; przeczże chcesz zburzyć dziedzictwo Pańskie?
Èmi ni ọ̀kan nínú àwọn ẹni àlàáfíà àti olóòtítọ́ ní Israẹli, ìwọ ń wá ọ̀nà láti pa ìlú kan run tí ó jẹ́ ìyá ní Israẹli, èéṣe tí ìwọ ó fi gbé ìní Olúwa mì.”
20 I odpowiedział jej Joab, mówiąc: Niedaj, niedaj mi tego Boże, abym miał podwrócić i zburzyć je.
Joabu sì dáhùn wí pé, “Kí a má rí i, kí a má rí i lọ́dọ̀ mi pé èmi gbé mì tàbí èmi sì parun.
21 Nie takci się rzecz ma. Ale mąż z góry Efraim, imieniem Seba, syn Bichry, podniósł rękę swą przeciw królowi Dawidowi; wydajcież go samego, a odciągnę od miasta. Zatem rzekła niewiasta do Jaoba: Oto głowę jego zrzucą do ciebie z muru.
Ọ̀ràn náà kò sì rí bẹ́ẹ̀; ṣùgbọ́n ọkùnrin kan láti òkè Efraimu, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ṣeba, ọmọ Bikri, ni ó gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè sí ọba, àní sí Dafidi: fi òun nìkan ṣoṣo lé wa lọ́wọ́, èmi ó sì fi ìlú sílẹ̀.” Obìnrin náà sì wí fún Joabu pé, “Wò ó, orí rẹ̀ ni a ó sì sọ láti inú odi wá.”
22 A tak sprawiła to ona niewiasta u wszystkigo ludu mądrością swoją, że ściąwszy głowę Sebie, synowi Bichry, zrzucili ją do Jaoaba; który zatrąbił w trąbę, i rozeszli się wszyscy od miasta, każdy do namiotów swoich; Joab się też wrócił do króla do Jeruzalemu.
Obìnrin náà sì mú ìmọ́ràn rẹ̀ tọ gbogbo àwọn ènìyàn náà, wọ́n sì bẹ Ṣeba ọmọ Bikri lórí, wọ́n sì sọ ọ́ sí Joabu. Òun sì fún ìpè, wọ́n sì túká ní ìlú náà, olúkúlùkù sí àgọ́ rẹ̀. Joabu sí padà lọ sí Jerusalẹmu àti sọ́dọ̀ ọba.
23 I był Joab hetmanem nad wszystkiem wojskiem Izraelskiem, a Banajas, syn Jojady, nad Chretczykami i nad Feletczykami.
Joabu sì ni olórí gbogbo ogun Israẹli; Benaiah ọmọ Jehoiada sì jẹ́ olórí àwọn Kereti, àti ti àwọn Peleti.
24 Adoram był poborcą, a Jozafat, syn Ahiluda, kanclerzem.
Adoniramu sì jẹ́ olórí àwọn agbowó òde; Jehoṣafati ọmọ Ahiludi sì jẹ́ olùkọsílẹ̀ ohun tí ó ń ṣẹlẹ̀ ní ìlú.
25 Seja pisarzem, a Sadok i Abijatar byli kapłanami.
Ṣefa sì jẹ́ akọ̀wé; Sadoku àti Abiatari sì ni àwọn àlùfáà.
26 Hira także Jairtczyk był książęciem u Dawida.
Ira pẹ̀lú, ará Jairi ni ń ṣe àlùfáà lọ́dọ̀ Dafidi.

< II Samuela 20 >