< Luke 21 >

1 Nígbà tí ó sì gbé ojú sókè, ó rí àwọn ọlọ́rọ̀ ń fi ẹ̀bùn wọn sínú àpótí ìṣúra.
Nau haeejaāne, nau haenauhauvā nethauyāsenanene haejenanauwu hevaudenenau haenathaunaa.
2 Ó sì rí tálákà opó kan pẹ̀lú, ó ń sọ owó idẹ wẹ́wẹ́ méjì síbẹ̀.
Nau haenauhauva jea jachau hadavenuhu henevesāne haethāgudene hanesāenee nevaāhenee vāejethāau.
3 Ó sì wí pé, “Lóòótọ́ ni mo wí fún yín, tálákà opó yìí fi sí i ju gbogbo wọn lọ,
Nau hanaāenehede, hethauwuu nananenau nāedauwunathana henee naa hadavenuhunede henevesā javaājenanauau vahee;
4 nítorí gbogbo àwọn wọ̀nyí fi sínú ẹ̀bùn Ọlọ́run láti ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìní wọn; ṣùgbọ́n òun nínú àìní rẹ̀ ó sọ gbogbo ohun ìní rẹ̀ tí ó ní sínú rẹ̀.”
Hanau vahee nuu nanethauyādahethee dejenanuu dejenanauwunauthee Hejavaneathu: hau hadavenuhunede hajenanauau vahee heenaededaunau hathāenethenauau.
5 Bí àwọn kan sì ti ń sọ̀rọ̀ nípa tẹmpili, bí a ti fi òkúta dáradára àti ẹ̀bùn ṣe é ní ọ̀ṣọ́, fun Ọlọ́run, Jesu wí pé
Nau haehegaugaugauudenauau vadannauauwuu, haseneehenee nauguu hethāhenethe hauunauganau nau hausāyaunau, hanaāenehede,
6 “Ohun tí ẹ̀yin ń wò wọ̀nyí, ọjọ́ ń bọ̀, nígbà tí a kì yóò fi òkúta kan sílẹ̀ lórí èkejì tí a kì yóò wó lulẹ̀.”
Nuu hayauhuhau hānauhauthaunenau, hesee hadnauauchuu, hadnehauwunathauau hanesāde hauunauga hanathaugude hadvajanesee.
7 Wọ́n sì béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, pé, “Olùkọ́, nígbà wo ni nǹkan wọ̀nyí yóò rí bẹ́ẹ̀? Àti àmì kín ni yóò wà, nígbà tí nǹkan wọ̀nyí yóò fi ṣẹ?”
Nau hanaāenaudedaunauthee, Hechauhauthethāhe, hau hadduunaasau nuu? nau hayew hadnauhauwuu hadnesauau hāene nuu hayauhuhau hadneenauauchuu? hathauhaugaunee.
8 Ó sì wí pé, “Ẹ máa kíyèsára, kí a má bá à mú yín ṣìnà: nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ yóò wá ní orúkọ mi, tí yóò máa wí pé, ‘Èmi ní Kristi náà àkókò náà sì kù sí dẹ̀dẹ̀.’ Ẹ má ṣe tọ̀ wọ́n lẹ́yìn.
Nau hanaāenehede, haunauyauhaudauwauau henee nananena hadejenanedaunehana: hanau hadnewauthathee hadjauthee Naneseedaunaa, Hanejavaneauthusaunenenau, hadnethee; nau hayānauauchauau: jevathauguhaa.
9 Ṣùgbọ́n nígbà tí ẹ̀yin bá gbúròó ogun àti ìdágìrì, ẹ má ṣe fòyà; nítorí nǹkan wọ̀nyí ní láti kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀, ṣùgbọ́n òpin náà kì í ṣe lójúkan náà.”
Hau hāenedauwaudauwunā vauthadede nau jajayauthadede, jeva nathajauau, hanau nuu hayauhuhau hadnedauunauauchuu; hau hadneevadauauau hadguthauau.
10 Nígbà náà ni ó wí fún wọn pé, “Orílẹ̀-èdè yóò dìde sí orílẹ̀-èdè, àti ìjọba sí ìjọba.
Hanaāāedauwunaude, jajaesenanedanedede hadnevauthadee jajaesenanedaa, nau najanede hadnevaudauau najanede:
11 Ilẹ̀-rírì ńlá yóò sì wà káàkiri, àti ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn; ohun ẹ̀rù, àti àmì ńlá yóò sì ti ọ̀run wá.
Nau hadnavathethauthauwunauauau vedauauawuu, nau hasenaude, nau havathaugauwude, nau naunaunauchaudauhauthaude nau hadvasauau naunauhauwuu hadnauauchauau hehethee hejavaa.
12 “Ṣùgbọ́n ṣáájú gbogbo nǹkan wọ̀nyí, wọn ó nawọ́ mú yín, wọn ó sì ṣe inúnibíni sí yín, wọn ó mú yín lọ sí Sinagọgu, àti sínú túbú, wọn ó mú yín lọ sọ́dọ̀ àwọn ọba àti àwọn ìjòyè nítorí orúkọ mi.
Hau hadnejesejenauauchuu vahee nuu, hadnedanāna, nau hadnaunaunauchauthehāna, nau hadnevaudenee nananena hauāchaude, nau duguhunauauwuu, nau hadnenauuchauhana hathaājethee nenauchuwuthee nau hauchuwunanenauau hanau Naneseede heee.
13 Ẹ o si jẹ́rìí nípa mi.
Nau hadnaasejenanauwunana heee haenathau.
14 Nítorí náà ẹ pinnu rẹ̀ ní ọkàn yín pé ẹ ko ronú ṣáájú, bí ẹ ó ti dáhùn.
Hāenauwuu heeehena nananena hadahenauau, jevagaugauuthajauau nedauau daun hadnesenehena:
15 Nítorí tí èmi ó fún yín ní ẹnu àti ọgbọ́n, tí gbogbo àwọn ọ̀tá yín kì yóò lè sọ̀rọ̀-òdì sí, tí wọn kì yóò sì lè kò lójú.
Hanau hadvenathana vade nau haeyaude, vahee hasānavādaunenau hadnehauwuneayādaunāva hegau hayethaagudaunādaunenau.
16 A ó sì fi yín hàn láti ọwọ́ àwọn òbí yín wá, àti àwọn arákùnrin, àti àwọn ìbátan, àti àwọn ọ̀rẹ́; òun ó sì mú kì a pa nínú yín.
Nau nananena hadnavethevāthee nesauuu hanehānenau, nau hāthesaunenau, nau hādauānenau, nau hādaehahenau; nau jasae nanaena hadneenaana.
17 A ó sì kórìíra yín lọ́dọ̀ gbogbo ènìyàn nítorí orúkọ mi.
Nau hadneevahasānavāhena vahee henanedaa hanau naneseede heee.
18 Ṣùgbọ́n irun orí yín kan kì yóò ṣègbé.
Hau hegau hāthaanenau haudauguhuanenauau haudnehauwugaujauaudāhenaunau.
19 Nínú ìdúró ṣinṣin yín ni ẹ̀yin ó jèrè ọkàn yín.
Hanāedevedaunenau hadnaunaunehaudde havadathuwunau.
20 “Nígbà tí ẹ̀yin bá sì rí ti a fi ogun yí Jerusalẹmu ká, ẹ mọ̀ nígbà náà pé, ìsọdahoro rẹ̀ kù sí dẹ̀dẹ̀.
Nau hāenauhaudauwunā Dādaunedan hadnechauchuaunāna vanenanenauau, nanehāaenauwuna henee nauauhadede wauwu hadneaudaa,
21 Nígbà náà ni kí àwọn tí ń bẹ ní Judea sálọ sórí òkè; àti àwọn tí ń bẹ láàrín rẹ̀ kí wọn jáde kúrò; kí àwọn tí ó sì ń bọ̀ ní ìgbèríko má ṣe wọ inú rẹ̀ wá.
Nanehadaugauhuthee hesee hauanee hathāanedauthee Judaea; nau henee hathāanedauthee nahethāe nanehanauahethee; nau jevajejedānauha henee hathāanedauthee gauchuhunee vedauauwuu.
22 Nítorí ọjọ́ ẹ̀san ni ọjọ́ wọ̀nyí, kì a lè mú ohun gbogbo tí a ti kọ̀wé rẹ̀ ṣẹ.
Hanau nuu hesee hadneauthedaudenee henee vahee hayauhuhau hathāewauthaunauhuu hadnethauwunaasauau.
23 Ṣùgbọ́n ègbé ni fún àwọn tí ó lóyún, àti àwọn tí ó fi ọyàn fún ọmọ mu ní ọjọ́ wọ̀nyí! Nítorí tí ìpọ́njú púpọ̀ yóò wà lórí ilẹ̀ àti ìbínú sí àwọn ènìyàn wọ̀nyí.
Hau naunauthaunee hadnethauauvāhethee hathāenesaunethee, nau hathāeneaunauhuthee hena hesee, hanau hena hadnavathasenaudenee vedauauwuu, nau hasenaunaudaunāhenauau nuu henanedanede.
24 Wọn ó sì ti ojú idà ṣubú, a ó sì dìwọ́n ní ìgbèkùn lọ sí orílẹ̀-èdè gbogbo; Jerusalẹmu yóò sì di ìtẹ̀mọ́lẹ̀ lẹ́sẹ̀ àwọn aláìkọlà, títí àkókò àwọn aláìkọlà yóò fi kún.
Nau hadneaunathāhethee gaugauthau, nau hadnejathechauhāthee hadwauwaunenethee vahee jajaesenanedanede: nau Dādaunedan hadnauguhethee Neauthu, haunaude Neauthu nauauchaudauhaugaunee.
25 “Àmì yóò sì wà ní oorun, àti ní òṣùpá, àti ní ìràwọ̀; àti lórí ilẹ̀ ayé ìdààmú fún àwọn orílẹ̀-èdè nínú ìpayà híhó Òkun àti ìgbì omi.
Nau hadnauhauthaunee hesesee, nau vegusesee, nau hauthuuu; nau nanadee hathāauauvaa hadnaunauādaugauhudaunee jajaesenanedanede, hadnehauwaenauwu; hadaje nau hadnaunaudānaunee;
26 Àyà àwọn ènìyàn yóò máa já fún ìbẹ̀rù, àti ìrètí nǹkan wọ̀nyí tí ń bọ̀ sórí ayé: nítorí àwọn agbára ọ̀run ni a ó mì tìtì.
Henanenauau hedahenau hadnadenāthajaunee, nau hanau naunauyauhauduu hena hayauhuhau hadnauauchaunee dasee hathāauauvaa, hanau hathāenauthauau hejavaa hadnauauwunauauau.
27 Nígbà náà ni wọn ó sì rí Ọmọ Ènìyàn tí yóò máa bọ̀ wá nínú àwọsánmọ̀ pẹ̀lú agbára àti ògo ńlá.
Nau hadnaāenauhauwauna Heau henane hadnenauusade henaunauade nauguu naunauthaunee nau hadnavathenauasāauau.
28 Ṣùgbọ́n nígbà tí nǹkan wọ̀nyí bá bẹ̀rẹ̀ sí í ṣẹ, ǹjẹ́ kí ẹ wo òkè, kí ẹ sì gbé orí yín sókè; nítorí ìdáǹdè yín kù sí dẹ̀dẹ̀.”
Nau hāene nuu hayauhuhau hāenauauchuu, nauhadnaāenaunauānena; nau hadnejenāauguauna heee hadneejaenauthana hadnaāeaudaa.
29 Ó sì pa òwe kan fún wọn pé, “Ẹ kíyèsi igi ọ̀pọ̀tọ́, àti sí gbogbo igi.
Nau hanaāedadajenehethaude; Nauhauvaa hauuyauchunauhaude, nau vahee hahaudenauau;
30 Nígbà tí wọ́n bá rúwé, ẹ̀yin rí i, ẹ sì mọ̀ fúnra ara yín pé, ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn kù fẹ́ẹ́rẹ́.
Hāeguugauāhenauthe, hadnauhauwauna nau hadnaenauwuna nehayau henee veja dauhuaudaa.
31 Gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ náà ni ẹ̀yin, nígbà tí ẹ̀yin bá rí nǹkan wọ̀nyí tí o ṣẹ, kí ẹ̀yin mọ̀ pé, ìjọba Ọlọ́run kù sí dẹ̀dẹ̀.
Hadnaasauau nananena hāenauhaudauwunā nuu hayauhuhau hadnethauwunaasauau, hāenauwuu henee henajanede Hejavaneauthau haneaudanee.
32 “Lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ìran yìí kì yóò rékọjá, títí gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò fi ṣẹ.
Hethauwuu nāedauwunathana, nuu henaedede hadnehauwuvadauau, haunaude vahee hadnethauvāe.
33 Ọ̀run àti ayé yóò rékọjá, ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ mi kì yóò rékọjá.
Hejavaa nau vedauauwuu hadneyauhuu; hau Nadanadedaunau hadnehauwuthauuyauhuunau.
34 “Ṣùgbọ́n ẹ máa kíyèsára yín, kí ọkàn yín má ṣe kún fún wọ̀bìà, àti fún ọtí àmupara, àti fún àníyàn ayé yìí, tí ọjọ́ náà yóò sì fi dé bá yín lójijì bí ìkẹ́kùn.
Nau haunauyauhaudauwauau nehayau, naseduhuu daunāene hadahenau havaehayaudenau heee haudauhauganedaunenau, nau havanadenenau, nau haunaunethaunenau nuu henaedede, nau henee hesee hadgauduaunāna hau hadnehauwaenava.
35 Nítorí bẹ́ẹ̀ ni yóò dé bá gbogbo àwọn tí ń gbé orí gbogbo ilẹ̀ ayé.
Hanau waude nauyaudenau hadnauauchauau vahee hathāetheaugude dasee hathāauauvaa.
36 Ǹjẹ́ kì ẹ máa ṣọ́nà, kí ẹ sì máa gbàdúrà nígbà gbogbo, kí ẹ ba à lè la gbogbo nǹkan wọ̀nyí tí yóò ṣẹlẹ̀, kí ẹ sì lè dúró níwájú Ọmọ Ènìyàn.”
Haunauyauhaudauwauau henaheee, nau hevevethahee dajauaunee, henee nananena hadeheenauguana hadegauchuhuauwuna vahee nuu hayauhuhau henee hadnauauchuu, nau haddetheauguna hathaāhede Heau henane.
37 Lọ́sàn án, Jesu a sì máa kọ́ni ní tẹmpili, lóru, a sì máa jáde lọ í wọ̀ ní òkè tí à ń pè ní Òkè Olifi.
Nau hesenee haeechauhauthethā vadanauauwuu; nau hāeveeyaunee haenauā, nau haeadāne hauanee henee neseeyāgu hauanee Olives.
38 Gbogbo ènìyàn sì ń tọ̀ ọ́ wá ní tẹmpili ní kùtùkùtù òwúrọ̀, láti gbọ́rọ̀ rẹ̀.
Nau vahee henanedanede haejevanauuchaudene naugusāje daunauganenee hadaude vadannauauwuu, heee dauhujaathehāde.

< Luke 21 >