< Luke 16 >

1 Ó sì wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pẹ̀lú pé, “Ọkùnrin ọlọ́rọ̀ kan wà, tí ó ní ìríjú kan; òun náà ni wọ́n fi sùn ún pé, ó ti ń fi ohun ìní rẹ̀ ṣòfò.
Jesu ing a hubatkhqi venawh: “Thlang boei pynoet awm nawh anih a tangka ak khoemkung ing tangka poeih pe kang hy tinawh amik kqawn ce zahy.
2 Nígbà tí ó sì pè é, ó wí fún un pé, ‘Èéṣe tí èmi fi ń gbọ́ èyí sí ọ? Ṣírò iṣẹ́ ìríjú rẹ; nítorí ìwọ kò lè ṣe ìríjú mi mọ́.’
Cedawngawh a boei ing khy nawh doet hy, ‘Na kawng kang zaak ve ikawmyihna a awmnaak? Tangka na khoem ce nim huh lah, ka tangka ak koemkung na am awm hly voel hyk ti,’ tina hy.
3 “Ìríjú náà sì wí nínú ara rẹ̀ pé, ‘Èwo ni èmi ó ṣe? Nítorí tí olúwa mi gba iṣẹ́ ìríjú lọ́wọ́ mi: èmi kò le ṣiṣẹ́ oko, bẹ́ẹ̀ ni ojú ń tì mí láti ṣagbe.
Cedawngawh tangka ak khoemkung ing ‘ikawmyihna nu ka ti lah kaw? Ka boeipa ing ka bibi awm ni qoek hly sak hawh hy. Dek deng aham awm kak tha am awm koek, thlang a venawh kut dun aham awm chak koek bai nyng.
4 Mo mọ èyí tí èmi yóò ṣe, nígbà tí a bá mú mi kúrò níbi iṣẹ́ ìríjú, kí àwọn ènìyàn le gbà mí sínú ilé wọn.’
Ka sai hly taw sim hawh nyng, cawh ni bibi ani phawh awhtaw thlangkhqi ing kai ve ami im awh ami ni do hly hy,’ tihy.
5 “Ó sì pe àwọn ajigbèsè olúwa rẹ̀ sọ́dọ̀ rẹ̀, ó sì wí fún èkínní pé, ‘Èló ni ìwọ jẹ olúwa mi?’
Cedawngawh a boeipa a ik-oeih ak pukhqi ce khy hy. Lamma cyk awhkaw thlang ce khy nawh, ‘Ka boeipa a koe ik-oeih izah nu nak pu peek? tina hy.
6 “Ó sì wí pé, ‘Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rún òsùwọ̀n òróró.’ “Ó sì wí fún un pé, ‘Mú ìwé rẹ, sì jókòó nísinsin yìí, kí o sì kọ àádọ́ta lé ní irinwó.’
Anih ing, ‘Olive situi boet zaqeet,’ tina hy. Law lah, ang tawnna ngawi nawhtaw zali na sai mai,’ tina hy.
7 “Nígbà náà ni ó sì bi ẹnìkejì pé, ‘Èló ni ìwọ jẹ?’ “Òun sì wí pé, ‘Ẹgbẹ̀rún òsùwọ̀n alikama.’ “Ó sì wí fún un pé, ‘Mú ìwé rẹ, kí o sì kọ ẹgbẹ̀rin.’
Cekcoengawh a pak khihnaak awhkaw thlang ce doet tlaih bai hy, ‘Nang law izah nak pu? tina hy. “Anih ing, ‘Canghum sum thongkhat,’ tina hy. Tangka ak pukung ing, ‘Nak punaak cahawn ce lo nawhtaw sum zaqeet na sai mai,’ tina hy.
8 “Olúwa rẹ̀ sì yin aláìṣòótọ́ ìríjú náà, nítorí tí ó fi ọgbọ́n ṣe é, àwọn ọmọ ayé yìí sá à gbọ́n ní ìran wọn ju àwọn ọmọ ìmọ́lẹ̀ lọ. (aiōn g165)
Amak thym na bi ak bi tangka ak khoemkung ing cyihnaak ing bi a bi dawngawh a boeipa ing kyih am cah hy. Ve khawmdek thlangkhqi ing a mimah a ik-oeih ami sai awhtaw vangnaak khuiawh ak awmkhqi anglakawh awm cyi ngai uhy. (aiōn g165)
9 Èmi sì wí fún yín, ẹ fi ọrọ̀ ayé yìí yan ọ̀rẹ́ fún ara yín pé, nígbà tí o ba lọ, kí wọn kí ó le gbà yín sí ibùjókòó wọn títí ayé. (aiōnios g166)
Nangmih a venawh ka nik kqawn peek khqi, pyi sainaak aham khawmdek boeinaak ce hawna lah uh, cawh ni ce mihkhqi boeih a boeih coengawh, a mingmih ing kumqui awmnaak hun awh nangmih ce ani do hly khqi hy. (aiōnios g166)
10 “Ẹni tí ó bá ṣe olóòtítọ́ nínú ohun kínkínní, ó ṣe olóòtítọ́ ní púpọ̀ pẹ̀lú: ẹni tí ó bá sì ṣe aláìṣòótọ́ ní ohun kínkínní, ó ṣe aláìṣòótọ́ ní ohun púpọ̀ pẹ̀lú.
U awm ik-oeih a khoehca awh ypawm na ak awm taw ik-oeih khawzah awh awm ypawm na awm hy, cehlai ik-oeih a khoehca awh ypawm na amak awm taw ik-oeih khawzah awh awm upvoet na awm hy.
11 Ǹjẹ́ bí ẹ̀yin kò bá ti jẹ́ olóòtítọ́ nínú ọrọ̀ ayé yìí, ta ni yóò fi ọ̀rọ̀ tòótọ́ fún yín?
Khawmdek boeinaak awh zani ama ypawm awhtaw, u ing nu boeimangnaak tang tang ce ani khoem sak kaw?
12 Bí ẹ̀yin kò bá sì ti jẹ́ olóòtítọ́ nínú ohun tí í ṣe ti ẹlòmíràn, ta ni yóò fún yín ní ohun tí í ṣe ti ẹ̀yin tìkára yín?
Thlang a ik-oeih awh ypvoet na na awm coengawh taw, u ing nu nang ce ik-oeih a ni peek kaw?
13 “Kò sì í ẹnìkan tí ó lè sin ọ̀gá méjì. Òun yóò yà kórìíra ọ̀kan tí yóò fẹ́ràn èkejì, tàbí kí ó fi ara mọ́ ọ̀kan kí ó sì yan èkejì ní ìpọ̀sí. Ẹ̀yin kò lè sin Ọlọ́run àti owó papọ̀.”
Tyihzoeih thlang pynoet ing boei pakkhih a bi pakkhih am bawk thai hy. Pynoet ce sawh na kawmsaw pynoet ce lungna kaw, am awhtaw pynoet ce ypna kawmsaw pynoet taw hep kaw. Khawsa bi ingkaw tangka bi am bawk hly thai qen hyk ti,’ tinak khqi hy.
14 Àwọn Farisi, tí wọ́n ní ojúkòkòrò sì gbọ́ gbogbo nǹkan wọ̀nyí, wọ́n sì yọ ṣùtì sí i.
Tangka amik thintlawhnaak Farasikhqi ing ce ak awi ce a ming zaak awh Jesu ce qaih na uhy.
15 Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ni àwọn tí ń dá àre fún ara yín níwájú ènìyàn; ṣùgbọ́n Ọlọ́run mọ ọkàn yín, nítorí ohun ti a gbéga lójú ènìyàn, ìríra ni níwájú Ọlọ́run.
Jesu ing a mingmih a venawh, “Thlang amik huh awh nangmih ing thlakdyng na sa qu uhyk ti, cehlai Khawsa ing nangmih ak kawlung ce sim hy. Thlang ing a phu ak tlo soeih na a taak ce Khawsa mik huh awhtaw tyih cu hy.
16 “Òfin àti àwọn wòlíì ń bẹ títí di ìgbà Johanu, Láti ìgbà náà wá ni a ti ń wàásù ìròyìn ayọ̀ ìjọba Ọlọ́run, olúkúlùkù sì ń fi ipá wọ inú rẹ̀.
Johan a khuk dy ni anaa awi ingkaw tangkakhqi ca qee ce amik khypyi hy. Cekcoengawh kawng Khawsa ram awithang ce khypyi hawh uhy, thlang boeih ing ce ak khuiawh kun aham tha lo uhy.
17 Ṣùgbọ́n ó rọrùn fún ọ̀run òun ayé láti kọjá lọ, ju kí èyí tí ó kéré jù nínú òfin kí ó yẹ.
Anaa awi awhkaw a dek zet ce ang qeng anglakawhtaw khawk khan ingkaw khawmdek ang qeng zoei bet kaw.
18 “Ẹnikẹ́ni tí ó bá kọ aya rẹ̀ sílẹ̀, tí ó sì gbé ẹlòmíràn ní ìyàwó, ó ṣe panṣágà: ẹnikẹ́ni tí ó bá sì gbé, ẹni tí ọkọ rẹ̀ kọ̀sílẹ̀ ní ìyàwó náà, ó ṣe panṣágà.
U ingawm a zu thla nawh nuk chang a lawh awhtaw samphaih hy, thlang a zuk thlak ak zunaak awm samphaih toeng toeng hy.
19 “Ǹjẹ́ ọkùnrin ọlọ́rọ̀ kan wà, tí ó ń wọ aṣọ elése àlùkò àti aṣọ àlà dáradára, a sì máa jẹ dídùndídùn lójoojúmọ́.
Kuiqang thlang pynoet awm nawh hik thim ingkaw hi ak leek leek ing myngawi ang thoeihcam qu coengawh awm hly poepa hy.
20 Alágbe kan sì wà tí à ń pè ní Lasaru, tí wọ́n máa ń gbé wá kalẹ̀ lẹ́bàá ọ̀nà ilé rẹ̀, ó kún fún ooju,
Ak chawmkeng a keng awh Lazaru ak mingnaak kut ak dun thlang pynoet ce awm hy, a pum boeih na phoei ing bawm nawh,
21 Òun a sì máa fẹ́ kí a fi èérún tí ó ti orí tábìlì ọlọ́rọ̀ bọ́ sílẹ̀ bọ́ òun, àwọn ajá sì wá, wọ́n sì fá a ní ooju lá.
kuiqang a caboei awhkaw ak tla awkdik aidik ce ai aham ngaih hy. Uikhqi ing ak phoei ce leek pe uhy.
22 “Ó sì ṣe, alágbe kú, a sì ti ọwọ́ àwọn angẹli gbé e lọ sí oókan àyà Abrahamu: ọlọ́rọ̀ náà sì kú pẹ̀lú, a sì sin ín;
Cawhkaw kut ak dun thlang ce thi nawh khan ceityihkhqi ing Abraham a venna khyn uhy. Kuiqang thlang awm thi lawt nawh pup uhy.
23 Ní ipò òkú ni ó gbé ojú rẹ̀ sókè, ó ń bẹ nínú ìjìyà oró, ó sì rí Abrahamu ní òkèrè, àti Lasaru ní oókan àyà rẹ̀. (Hadēs g86)
Hell khuina khuikha a sim cilh cilh awh ak hla nakawng Abraham ingkaw a venawh Lazaru ak awm ce hu hy. (Hadēs g86)
24 Ó sì ké, ó wí pé, ‘Baba Abrahamu, ṣàánú fún mi, kí o sì rán Lasaru, kí ó tẹ orí ìka rẹ̀ bọ omi, kí ó sì fi tù mí ní ahọ́n; nítorí èmi ń joró nínú ọ̀wọ́n iná yìí.’
Ak khy doe na, ‘Ka pa Abraham, qeennaak ing Lazaru ce tyi nawhtaw tui awh a kutply pui seitaw kam lai ve ci law sak lah seh, vawhkaw mai awh ve khuikha cip cip hawh nyng ve,’ tina hy.
25 “Ṣùgbọ́n Abrahamu wí pé, ‘Ọmọ, rántí pé, nígbà ayé rẹ, ìwọ ti gba ohun rere tìrẹ, àti Lasaru ohun búburú, ṣùgbọ́n nísinsin yìí ara rọ̀ ọ́, ìwọ sì ń joró.
Cehlai Abraham ing, ‘Ka capa, na hqing khui pyt awh ik-oeih ak leek leek hu tiksaw, Lazaru taw ik-oeih che a huh ce poek lah, cehlai tuh awhtaw anih ing ngaihdingnaak hu nawh nang taw khuikha hyk ti.
26 Àti pẹ̀lú gbogbo èyí, a gbé ọ̀gbun ńlá kan sí agbede-méjì àwa àti ẹ̀yin, kí àwọn tí ń fẹ́ má ba á le rékọjá láti ìhín lọ sọ́dọ̀ yín, kí ẹnikẹ́ni má sì le ti ọ̀hún rékọjá tọ̀ wá wá.’
Vekkhqi boeih coengawh, nang ingkaw kaimih anglakawh lawk-kqawng ak dung soeih awm hy, cedawngawh vawhkawng nang a venna u awm am cet thai hy, nang a venna kawng vena u awm am law thai bai hy,’ tina hy.
27 “Ó sì wí pé, ‘Ǹjẹ́ mo bẹ̀ ọ́, baba, kí ìwọ kí ó rán Lasaru lọ sí ilé baba mi,
Cawh anih ing, ‘cawhtaw ka pa Abraham, qeennaak thoeh law nyng, Lazaru ce Ka pa im na tyi cang lah,
28 nítorí mo ní arákùnrin márùn-ún; kí ó lè rò fún wọn kí àwọn kí ó má ba á wá sí ibi oró yìí pẹ̀lú.’
Ka naa thlang pumha awm hyn hy. Vawhkaw khuikha simnaak a hun awh a mami lawnaak thai aham anih ing kqawn law pe cang lah seh nyng,’ tina hy.
29 “Abrahamu sì wí fún un pé, ‘Wọ́n ní Mose àti àwọn wòlíì; kí wọn kí ó gbọ́ tiwọn.’
Abraham ing, ‘Mosi ingkaw tawnghakhqi ta hawh usaw ti a; cekkhqi ak awi ce ngai mai u seh,’ tina hy.
30 “Ó sì wí pé, ‘Bẹ́ẹ̀ kọ́, Abrahamu baba; ṣùgbọ́n bí ẹnìkan bá ti inú òkú tọ̀ wọ́n lọ, wọn ó ronúpìwàdà.’
Anih ing, ‘Amni, ka pa Abraham, thlak thi ak khuiawh kawng thlang pynoet oet a mingmih a venna a ceh mantaw thawlh zut kawm uh,’ tina hy.
31 “Ó sì wí fún un pé, ‘Bí wọn kò bá gbọ́ ti Mose àti ti àwọn wòlíì, a kì yóò yí wọn ní ọkàn padà bí ẹnìkan tilẹ̀ ti inú òkú dìde.’”
Abraham ing a venawh, ‘Mosi ingkaw tawnghakhqi ak awi ce a maming ngai awhtaw, thihnaak ak khuiawh kawng thlang tho nawh kqawn pe bai seiawm am ngai hly uhy,’ tina hy,” tinak khqi hy.

< Luke 16 >