< Luke 12 >

1 Ó sì ṣe, nígbà tí àìníye ìjọ ènìyàn péjọpọ̀, tó bẹ́ẹ̀ tí wọn ń tẹ ara wọn mọ́lẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ sísọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ẹ máa ṣọ́ra yín nítorí ìwúkàrà àwọn Farisi tí í ṣe àgàbàgebè.
Ya yogu ke ku niwulgu den taani ki pundi a tuda, ke bi niba ji ŋmaadi bi lieba, ke o cili ki dá maadi leni o ŋɔdkaaba, “Fangi mani i yuli leni farisienba nɔbli, bani yaaba n pia mi muyima.
2 Kò sí ohun tí a bò, tí a kì yóò sì fihàn; tàbí tí ó pamọ́, tí a kì yóò mọ̀.
Ama bonlibá ki ye ki duagi, ki kan dɔgdi, bonli ki ye ki wuo, ke bi kan bandi.
3 Nítorí náà ohunkóhun tí ẹ̀yin sọ ní òkùnkùn, ní gbangba ni a ó ti gbọ́ ọ; àti ohun tí ẹ̀yin bá sọ sí etí ní iyàrá, lórí òrùlé ni a ó ti kéde rẹ̀.
Lanwani i, yin maadi yaali li biigli nni, bi ba gbadi li mi yenyenma nni, ke yin sɔbi ki maadi yaali li dieli nni, ke a gana luo, bi ba kpaandi la li dieli binbinli po.
4 “Èmi sì wí fún yín ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi, ẹ má ṣe bẹ̀rù àwọn tí ó ń pa ara ènìyàn kú, lẹ́yìn èyí, wọn kò sì ní èyí tí wọ́n lè ṣe mọ́.
N dɔnlinba, n yedi yi, da jie mani yaaba n ba kpa ti gbannandi, ki ji kan fidi ki tieni libá kuli ki pugni.
5 Ṣùgbọ́n èmi ó sì sọ ẹni tí ẹ̀yin ó bẹ̀rù fún yín: Ẹ bẹ̀rù ẹni tí ó lágbára lẹ́yìn tí ó bá pànìyàn tan, láti wọ́ ni lọ sí ọ̀run àpáàdì. Lóòótọ́ ni mo wí fún yín òun ni kí ẹ bẹ̀rù. (Geenna g1067)
Ama, n ba tuodi ki waani yi yin ba ya jie yua. Yin jie yua kpa, ki go pia ya paalu n ba lu ŋa ku mubuogu nni. Nn, n maadi yi, jie mani o. (Geenna g1067)
6 Ológoṣẹ́ márùn-ún sá à ni a ń tà ní owó idẹ wẹ́wẹ́ méjì? A kò sì gbàgbé ọ̀kan nínú wọn níwájú Ọlọ́run?
bi ki kuadi nuanmu mu mu ka kuumu lie e? Leni lani kuli, U Tienu nunga nni, bi kan sundi mu siiga nni bá yenga po.
7 Ṣùgbọ́n gbogbo irun orí yín ni a kà pé ṣánṣán. Nítorí náà kí ẹ má ṣe bẹ̀rù, ẹ̀yin ní iye lórí ju ológoṣẹ́ púpọ̀ lọ.
Ama yinba wani, bá i yudi, bi cɔdi ki bani ti dugli. Da jie mani pu, i pia muyuli ki cie ya nuankuli n yabi.
8 “Mo sì wí fún yín pẹ̀lú, Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́wọ́ mi níwájú àwọn ènìyàn. Ọmọ Ènìyàn yóò sì jẹ́wọ́ rẹ̀ níwájú àwọn angẹli Ọlọ́run.
N yedi yi, ya nilo kuli n tuo ke o bani nni, bi niba siiga, o 'Ja Bijua' mo ba tuo ke n bani o U Tienu malekinba kani.
9 Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá sẹ́ mi níwájú ènìyàn, a ó sẹ́ ẹ níwájú àwọn angẹli Ọlọ́run.
Ama yua nia bi niba siiga ke waa tie n yua, bi ba sundi o po U Tienu malekinba kani.
10 Àti ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ̀rọ̀-òdì sí Ọmọ Ènìyàn, a ó dárí rẹ̀ jì í; ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ̀rọ̀-òdì sí Ẹ̀mí Mímọ́, a kì yóò dárí rẹ̀ jì í.
Yua n maadi mabiadma o 'Ja Bijua' po, ba baa sugli, ama yua n maadi ki sugi U Tienu Foŋanma, o kan baa sugli.
11 “Nígbà tí wọ́n bá sì mú yin wá sí Sinagọgu, àti síwájú àwọn olórí, àti àwọn aláṣẹ, ẹ má ṣe ṣàníyàn pé, báwo tàbí ohun kín ni ẹ̀yin yóò fèsì rẹ̀ tàbí kín ni ẹ̀yin ó wí.
Bi ya dia yi, ki caa leni yi ti jaandiedi nni, ti buudi danba kani leni yikodanba kani ti buudi po, yin da yagi i yama leni yin ba maadi yaala ki fie i yuli, bii yin ba yedi yaala.
12 Nítorí Ẹ̀mí Mímọ́ yóò kọ́ yín ní wákàtí kan náà ní ohun tí ó yẹ kí ẹ sọ.”
Kelima lanyognu liga, U Tienu Foŋanma ba tundi yin ba yedi yaala.
13 Ọ̀kan nínú àwùjọ wí fún un pé, “Olùkọ́, sọ fún arákùnrin mi kí ó pín mi ní ogún.”
Ke niyendo yedi o ku niwulgu siiga “Canbaa, maadi n kpelo wan bɔgdi ti báa ń sieni ti ya faali, ki teni nni.
14 Ó sì wí fún un pé, “Ọkùnrin yìí, ta ni ó fi mí jẹ onídàájọ́ tàbí olùpíngún fún yín?”
Jesu ń yedi o, “O ja, ŋma n kaani nni ke min ya tie i buudidaano bii i ke min tua i kɔnpaadilo li faali bɔgdima po?
15 Ó sì wí fún wọn pé, “Kíyèsára kí o sì máa ṣọ́ra nítorí ojúkòkòrò: nítorí ìgbésí ayé ènìyàn kò dúró lé ọ̀pọ̀ ohun tí ó ní.”
Ki yedi ba, “Fangi mani yibá lini mi ŋalmanbuacianma, kelima nilo miali ki ŋua o ŋalmani yabmu ka.
16 Ó sì pa òwe kan fún wọn pé, “Ilẹ̀ ọkùnrin ọlọ́rọ̀ so ọ̀pọ̀lọpọ̀ èso.
Lani ke Jesu pua ba ya kpanjama ne, “Piado bá den koni ki baa boncianla,
17 Ó sì rò nínú ara rẹ̀ pé, ‘Èmi ó ti ṣe, nítorí tí èmi kò ní ibi tí èmi ó gbé kó èso mi jọ sí.’
ke o kali, ki jagi, ki yedi o pali nni, “N ji ba tieni ledi i, kelima mii ji pia kaanu ki ba bili n kpaandi ne kuli?
18 “Ó sì wí pé, ‘Èyí ni èmi ó ṣe: èmi ó wó àká mi palẹ̀, èmi ó sì kọ́ èyí tí ó tóbi; níbẹ̀ ni èmi ó gbé to gbogbo èso àti ọrọ̀ mi jọ sí.
ki yedi, “Min ba tieni maama n ne. N ba mumudi n bunbuana, ki guani ki ma yia n tiani, ki bili lien nni n bondikaali leni n bonpiakaali kuli.
19 Èmi ó sì wí fún ọkàn mi pé, ọkàn, ìwọ ní ọrọ̀ púpọ̀ tí a tò jọ fún ọ̀pọ̀ ọdún; sinmi, máa jẹ, máa mu, máa yọ̀.’
Lani, n ji ba pagi n yuli “Mini, min bili ya piama kandi, ki ba tuoni nni ya bina n yabi. Ya kaa, ki fuo, ki di, ki ñu, ki mangdi a pali.
20 “Ṣùgbọ́n Ọlọ́run wí fún un pé, ‘Ìwọ aṣiwèrè, lóru yìí ni a ó béèrè ọkàn rẹ lọ́wọ́ rẹ; ǹjẹ́ ti ta ni nǹkan wọ̀nyí yóò ha ṣe, tí ìwọ ti pèsè sílẹ̀?’
Ama, ke U Tienu yedi o “O yanluodaano ne, dinne ñiagu liga i, ke n ba ñani a naano, ki ŋa a. ŋan bili yaali kuli ba tua ŋma ya yaali i?
21 “Bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó to ìṣúra jọ fún ara rẹ̀, tí kò sì ní ọrọ̀ lọ́dọ̀ Ọlọ́run.”
Li tie nani yua n taagi mi piama o yuli po, ki nan ki pia pu U Tienu kani.”
22 Jesu sì wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Nítorí náà mo wí fún yín pé, ẹ má ṣe ṣe àníyàn nítorí ẹ̀mí yín pé, kín ni ẹ̀yin yóò jẹ tàbí nípa ara yin pe kín ni ẹyin o fi bora.
Jesu yedi o ŋɔdkaaba, “lanwani i, yin da buali i miali po, yin ba di yaali bii, i gbanu po, li bonlakaali po
23 Ẹ̀mí sá à ju oúnjẹ lọ, ara sì ju aṣọ lọ.
Kelima, li miali gie ti jiedi, ke u gbanu mo cie ti tialakaadi.
24 Ẹ kíyèsi àwọn ẹyẹ ìwò: wọn kì í fúnrúgbìn, bẹ́ẹ̀ ni wọn kì í kórè: wọn kò ní àká, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní abà, Ọlọ́run sá à ń bọ́ wọn: mélòó mélòó ni tí ẹ̀yin fi sàn ju ẹyẹ lọ!
Diidi mani a bonyugda, baa buu, baa yendi, baa pia bilkaanu, baa pia bɔnbuana, ama U Tienu nan dingi a. yinba, i pia mayuli ki cie ti bonyugditi!
25 Ta ni nínú yín nípa àníyàn ṣíṣe tí ó lè fi ìgbọ̀nwọ́ kan kún ọjọ́ ayé rẹ̀?
I siiga, ŋma ba fidi ki fagni o miali bá a dana waamu?
26 Ǹjẹ́ bí ẹ̀yin kò ti lè ṣe èyí tí ó kéré bí eléyìí, èéṣe tí ẹ̀yin fi ń ṣàníyàn nítorí ìyókù?
I ya ya bani ke i kan fidi ki tieni yaali n waa ki cie ne, be ya po i ke i maali yaali n sieni kuli po o?
27 “Ẹ kíyèsi àwọn lílì bí wọ́n ti ń dàgbà; wọn kì í ṣiṣẹ́, wọn kì í rànwú; ṣùgbọ́n kí èmi wí fún yín, a kò ṣe Solomoni pàápàá lọ́ṣọ̀ọ́ ní gbogbo ògo rẹ̀ tó ọ̀kan nínú ìwọ̀nyí.
Diidi mani ti puudi ń tie maama, tii tuuni, tii pia gaalu mo, ama bá o badciamo Salomɔn leni o kpiagdi, waa pundi bi siiga bá yengu ń bobi maama.
28 Ǹjẹ́ bí Ọlọ́run bá wọ koríko igbó ní aṣọ tó bẹ́ẹ̀ èyí tí ó wà lónìí, tí a sì gbá a sínú iná lọ́la: mélòó mélòó ni yóò wọ̀ yín láṣọ, ẹ̀yin onígbàgbọ́ kékeré.
U Tienu ya bobindi u kuanu nni muadi yeni, tini yaadi ye dinne ke bi ba faa ki taa ti, ki kuuni u fanu nni, ki cuoni umu, li ki pia tama ke o ba bobni yi mo, oo yinba yaaba ya dudugdi n ki pia fuoma!
29 Kí ẹ má sì ṣe lé ohun tí ẹ ó jẹ, tàbí ohun tí ẹ ó mu, kí ẹ má sì ṣe ṣe àníyàn nínú ọkàn.
Da buali mani yin ba di yaali leni yin ba ñu yaali po, ki go da yagni i yama.
30 Nítorí gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni àwọn orílẹ̀-èdè ayé ń wá kiri. Baba yín sì mọ̀ pé, ẹ̀yin ń fẹ́ nǹkan wọ̀nyí.
Kelima ŋanduna dogi kuli lingi lanya bona i, ke i Báa moko bani ke i bua li bona.
31 Ṣùgbọ́n ẹ máa wá ìjọba Ọlọ́run, gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni a ó sì fi kún un fún yín.
Ama yin lingi mani o diema, i ba baa lanya bona ki pugni
32 “Má bẹ̀rù, agbo kékeré, nítorí dídùn inú Baba yín ni láti fi ìjọba fún yín.
Da jie mani ba waamu, kelima i Báa pali mani ke wan puni yi o diema.
33 Ẹ ta ohun tí ẹ̀yin ní, kí ẹ sì tọrẹ àánú kí ẹ sì pèsè àpò fún ara yín, tí kì í gbó, ìṣúra ní ọ̀run tí kì í tán, ní ibi tí olè kò lè súnmọ́, àti ibi tí kòkòrò kì í bà á jẹ́.
Kuadi mani i piama, ki puni a luoda li ligi. ŋali mani i po ya ligbɔgli n kan cadi, ŋaljanli nni ya ŋalmani yaali n ki pia gbenma.
34 Nítorí ní ibi tí ìṣúra yín gbé wà, níbẹ̀ ni ọkàn yín yóò gbé wà pẹ̀lú.
Kelima a ŋalmani ń ye naani, a pali mo ye lankani i.
35 “Ẹ di àmùrè yín, kí fìtílà yín sì máa jó.
N̄agni mani i liadfagda u gbanñagdu, i fidsanmu ń ya tundi ki co;
36 Kí ẹ̀yin tìkára yín dàbí ẹni tí ń retí olúwa wọn, nígbà tí òun ó padà ti ibi ìgbéyàwó dé, pé nígbà tí ó bá dé, tí ó sì kànkùn, kí wọn lè ṣí i sílẹ̀ fún un lọ́gán.
Yin ya tie nani ya niba n guu bi canbáa ń ba ña mi pocaajaama po, ki kpeni yeni, o ya pua li ganli ya yognu, ban kagni ki luodi o po.
37 Ìbùkún ni fún àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ náà nígbà tí olúwa náà bá dé tí yóò bá wọn tí wọn ń ṣọ́nà; lóòótọ́ ni mo wí fún yín, yóò di ara rẹ̀ ní àmùrè yóò sì mú wọn jókòó láti jẹun, yóò sì jáde wá láti ṣe ìránṣẹ́ fún wọn.
Ya tuonsɔnba, ke bi canbáa ba pundi ki sua ke bi dá nua, bani baa mi yedŋanma n yeni. I mɔmɔni, n maadi yi, o ba ñagni o gaaligu u gbanñagdu, ki cedi ban kali u jedikaanu, wan tieni ba mi jiema ban je.
38 Bí olúwa wọn bá sì dé nígbà ìṣọ́ kejì, tàbí tí ó sì dé nígbà ìṣọ́ kẹta, tí ó sì bá wọn bẹ́ẹ̀, ìbùkún ni fún àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ náà.
Canbàa ya pundi yɔgsiigu bii siŋaafaani, ki sua ke bi cegni ki guu o, lan ya tuonsɔnba baa mi yedŋanma n yeni.
39 Ṣùgbọ́n ẹ mọ èyí pé, baálé ilé ìbá mọ wákàtí tí olè yóò wá, òun ìbá máa ṣọ́nà, kì bá tí jẹ́ kí a já wọ inú ilé òun.
Ama, min ba pugni yaali n ne, yin ya bani ke o diedaano ya bi bani ya yognu ke o suuro ba kua o deni ki suu o, o bi kan ŋa ban kua o deni ki su o,
40 Nítorí náà, kí ẹ̀yin múra pẹ̀lú, nítorí Ọmọ Ènìyàn ń bọ̀ ní wákàtí tí ẹ̀yin kò nírètí.”
Yin egni iba, ki ya guu kelimaa i ki baniO Ja bijua n ́ ba guaniya yognu.
41 Peteru sì wí pé, “Olúwa, ìwọ pa òwe yìí fún wa, tàbí fún gbogbo ènìyàn?”
Pieri ń buali: «O Diedo, a pua lan ya kpanjama tinba baba ya po bii, li tie yuakuli ya po i?»
42 Olúwa sì dáhùn wí pé, “Ta ni olóòtítọ́ àti ọlọ́gbọ́n ìríjú náà, tí olúwa rẹ̀ fi jẹ olórí agbo ilé rẹ̀, láti máa fi ìwọ̀n oúnjẹ wọ́n fún wọn ní àkókò?
O Diedo ń yedi: «O laa tuonsɔnlo i, ke o canbáa ba guuni ke wan ya diidi o tuonsɔnlieba tuona, ki puuni ba bi daali jiema lan buali ya yognu,
43 Ìbùkún ni fún ọmọ ọ̀dọ̀ náà, nígbà tí olúwa rẹ̀ bá dé, tí yóò bá a kí ó máa ṣe bẹ́ẹ̀.
o canbáa ya kpeni ki sua ke o tuuni lan buali maama, lanya tuonsɔnlo baa mi yedŋanma n yeni.
44 Lóòótọ́ ni mo wí fún yín yóò fi jẹ olórí ohun gbogbo tí ó ní.
I mɔmɔni n maadi yi, canbáa ba taa o piama kuli ki piani lanya tonsɔnlo.
45 Ṣùgbọ́n bí ọmọ ọ̀dọ̀ náà bá wí ní ọkàn rẹ̀, pé, ‘Olúwa mi fi ìgbà bíbọ̀ rẹ̀ falẹ̀!’ Tí ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í lu àwọn ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin tí ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í jẹ àti sí mu àmupara:
Ama li tuonsɔnlo ya maadi o pali nni: «N canbáa kpenma dá ba fagdi», ki ji cili ki pua o tuonsɔnlieba, bi jaba yeni bi puoba kuli, ki go cili ki di ki go ñu wan bua maama, ke mi daama ga o.
46 Olúwa ọmọ ọ̀dọ̀ náà yóò dé ní ọjọ́ tí kò retí rẹ̀, àti ní wákàtí tí kò dábàá, yóò sì jẹ ẹ́ ní yà gidigidi, yóò sì yan ipò rẹ̀ pẹ̀lú àwọn aláìgbàgbọ́.
O ya tie yeni, o canbáa ba ti ludi ki kpeni wan ki guu o ya yognu, ki cedi ban pua ki duoli o kaani kuli, ki beli ki ñani o, ki kuani o bi tuonsɔbiadba danba siiga nni.
47 “Àti ọmọ ọ̀dọ̀ náà, tí ó mọ ìfẹ́ olúwa rẹ̀, tí kò sì múra sílẹ̀, tí kò sì ṣe gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ rẹ̀, òun ni a ó nà púpọ̀.
Nani li tuosɔnlo ń den bani o canbáa ń bili o ya tuonli yeni i, ki nan ki sɔni lan buali maama yeni i, o canbáa ba cedi ban pua o ya lanbana n yabi.
48 Ṣùgbọ́n èyí tí kò mọ̀, tí ó ṣe ohun tí ó yẹ sí lílù, òun ni a ó lù níwọ̀n. Nítorí ẹnikẹ́ni tí a fún ní púpọ̀, lọ́dọ̀ rẹ̀ ni a ó gbé béèrè púpọ̀: lọ́dọ̀ ẹni tí a bá gbé fi púpọ̀ sí, lọ́dọ̀ rẹ ni a ó gbé béèrè sí i.
Ama, ya tuonsɔnlo n ki tuodi ki bani, ki sɔni ya tuonli n buali ke lan dadi o tubli ii, bi ba pua o lanbana waaamu. Ban teni yua ke li yabi, bi ba buali o yaali n yabi. Ban piani yua yaali n cie, bi ba buali o yaali n cie.
49 “Iná ni èmi wá láti sọ sí ayé; kín ni èmi sì ń fẹ́ bí kò ṣe kí iná náà ti jo!
«N cua ki tinga po ke min sia mu i. N sugni ke li mu ji co i.
50 Ṣùgbọ́n èmi ní bamitiisi kan tí a ó fi bamitiisi mi; ara ti ń ni mí tó títí yóò fi parí!
N pia mi ñinwulma, ke bi ba wuli nni. I ki bani min bua tonma maama, ke li kuli ń tieni ki tii.
51 Ẹ̀yin ṣe bí àlàáfíà ni èmi fi sí ayé? Mo wí fún yín, bẹ́ẹ̀ kọ́; ṣùgbọ́n bí kò ṣe ìyapa.
I tama ke n cua ki tinga po yeni mi yanduanma yo oo? N n! I mɔmɔni, n maadi yi, n cua yeni mi paadma i.
52 Nítorí láti ìsinsin yìí lọ, ènìyàn márùn-ún yóò wà ní ilé kan náà tí a ó yà ní ipa, mẹ́ta sí méjì, àti méjì sí mẹ́ta.
Kelimaa, lan cili mɔlane, dieyengu nni, niba mu ba paadi, niba lie ń kɔni yeni niba taa; niba taa mo ń kɔni yeni niba lie.
53 A ó ya baba nípa sí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, àti ọmọ ọkùnrin sí baba; ìyá sí ọmọbìnrin, àti ọmọbìnrin sí ìyá rẹ̀, ìyá ọkọ sí ìyàwó ọmọ, àti ìyàwó ọmọ sí ìyá ọkọ rẹ̀.”
Bi ba paadi bibáa ń kɔni yeni o bijaba, a bila mo ń kɔni yeni bibáa. Binaá ba kɔni yeni o bisiaba, a bisala mo ń kɔni yeni binaá. Calnaá ba kɔni yeni o biyuaga, ki biyuaga ń kɔni yeni calnaá.»
54 Ó sì wí fún ìjọ ènìyàn pẹ̀lú pé, “Nígbà tí ẹ̀yin bá rí àwọsánmọ̀ tí ó ṣú ní ìhà ìwọ̀-oòrùn, lọ́gán ni ẹ̀yin yóò sọ pé, ‘Ọ̀wààrà òjò ń bọ̀,’ a sì rí bẹ́ẹ̀.
Jesu go den maadi ku niwulgu yaali ne: «I ya la taayinbɔnu puoli, i yi maadi: “Ki taaga ba nii!” Lan go tieni yeni.
55 Nígbà tí afẹ́fẹ́ gúúsù bá ń fẹ́, ẹ̀yin á ní, ‘Oòrùn yóò mú,’ yóò sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Mi faawaama ya fii nintuali, i yi maadi: “Ku wulgu ba tieni!” Lan go tua yeni.
56 Ẹ̀yin àgàbàgebè! Ẹ̀yin le mòye ojú ọ̀run àti ti ayé. Èéha ti ṣe tí ẹ̀yin kò mọ àkókò yìí?
Yinba i muyiidmu ne! I fidi ki diidi ki tinga maalma yeni tanpoli maalma, ki bandi a bona. Li nan tieni ledi i, ke yi ki fidi ki bandi U tienu n ́ bobindi yaali mɔlane?
57 “Èéha ti ṣe tí ẹ̀yin tìkára yín kò fi ro ohun tí ó tọ́?
Li tieni ledi i, ke yi kan fidi ki tuodi ki cegni yaali n tiegi i po mɔlane?
58 Nígbà tí ìwọ bá bá ọ̀tá rẹ lọ sọ́dọ̀ onídàájọ́, rí i pé o bá a parí ọ̀rọ̀ ní ọ̀nà kí ó má ba à fà ọ́ fún adájọ́, adájọ́ a fi ọ́ lé ẹ̀ṣọ́ lọ́wọ́, òun a sì tì ọ́ sínú túbú.
A ya caa ti buudi yeni a yibali, ŋan mɔndi ki mangi yeni o u sanu nni, wan da ti cedi ti buudi yudanba ń buu ki cuo a, ban mubni a bi paatieba nui nni, ban luoni a li kpaadidieli nni.
59 Kí èmi wí fún ọ, ìwọ kì yóò jáde kúrò níbẹ̀, títí ìwọ ó fi san ẹyọ owó kan tí ó kù!”
N maadi a, a kan ña li kpaadidieli nni, kaa pani a pana kuli ki gbeni.»

< Luke 12 >