< Luke 12 >

1 Ó sì ṣe, nígbà tí àìníye ìjọ ènìyàn péjọpọ̀, tó bẹ́ẹ̀ tí wọn ń tẹ ara wọn mọ́lẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ sísọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ẹ máa ṣọ́ra yín nítorí ìwúkàrà àwọn Farisi tí í ṣe àgàbàgebè.
Laa yogunu ku niligu den taani tuda tuda ŋali ki ŋmaadi bi yaba. Jesu den cili ki maadi leni o ŋoadikaaba ki yedi: “Fangi mani yi yula ki da kubi falisieninba dabinli, lani n tie palalie yantiali.
2 Kò sí ohun tí a bò, tí a kì yóò sì fihàn; tàbí tí ó pamọ́, tí a kì yóò mọ̀.
Liba kuli ki ye ki wuo ki kan wuodi. Liba kuli ki ye ki duagi ke bi kan bandi la.
3 Nítorí náà ohunkóhun tí ẹ̀yin sọ ní òkùnkùn, ní gbangba ni a ó ti gbọ́ ọ; àti ohun tí ẹ̀yin bá sọ sí etí ní iyàrá, lórí òrùlé ni a ó ti kéde rẹ̀.
Lanyaapo yin baa yedi yaala li biigili nni kuli, bi baa gbadi la u yensiinu. Yin baa soabidi yaala yi diena nni, bi baa kpaani la bi niba kuli n gbadi.
4 “Èmi sì wí fún yín ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi, ẹ má ṣe bẹ̀rù àwọn tí ó ń pa ara ènìyàn kú, lẹ́yìn èyí, wọn kò sì ní èyí tí wọ́n lè ṣe mọ́.
Yinba n danlinba, n yedi yi, yin da jie mani yaala n baa kpa yi gbannandi ki nan kan fidi ki tieni yi bontoala.
5 Ṣùgbọ́n èmi ó sì sọ ẹni tí ẹ̀yin ó bẹ̀rù fún yín: Ẹ bẹ̀rù ẹni tí ó lágbára lẹ́yìn tí ó bá pànìyàn tan, láti wọ́ ni lọ sí ọ̀run àpáàdì. Lóòótọ́ ni mo wí fún yín òun ni kí ẹ bẹ̀rù. (Geenna g1067)
N baa waani yi yin baa jie yua. Ya jie mani yua n baa fidi ki kpa yi, ki go yuandi ki lu yi ku fantanbuogu nni. Yeni de, n yedi yi ke wani n tie yin baa jie yua. (Geenna g1067)
6 Ológoṣẹ́ márùn-ún sá à ni a ń tà ní owó idẹ wẹ́wẹ́ méjì? A kò sì gbàgbé ọ̀kan nínú wọn níwájú Ọlọ́run?
Baa kuadi nuani muu muu kaa kumu lie? Ama baa yeni, U Tienu kan sundi bi siiga nni ba yendo po.
7 Ṣùgbọ́n gbogbo irun orí yín ni a kà pé ṣánṣán. Nítorí náà kí ẹ má ṣe bẹ̀rù, ẹ̀yin ní iye lórí ju ológoṣẹ́ púpọ̀ lọ.
Yinba wani, baa yi yudi, U Tienu bani ti coali n da maama da jie mani pu kuli, yi pia mayuli ki cie i nuani boncianla.
8 “Mo sì wí fún yín pẹ̀lú, Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́wọ́ mi níwájú àwọn ènìyàn. Ọmọ Ènìyàn yóò sì jẹ́wọ́ rẹ̀ níwájú àwọn angẹli Ọlọ́run.
N yedi yi ke yua n tuo bi niba nintuali ke o tie n yua kuli, o Joa Bijua moko n baa tuo malekinba nintuali ke o tie n yua.
9 Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá sẹ́ mi níwájú ènìyàn, a ó sẹ́ ẹ níwájú àwọn angẹli Ọlọ́run.
Ama yua n nia bi niba nintuali ke waa tie n yua, n moko baa nia o U Tienu malekinba nintuali ke waa tie n yua.
10 Àti ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ̀rọ̀-òdì sí Ọmọ Ènìyàn, a ó dárí rẹ̀ jì í; ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ̀rọ̀-òdì sí Ẹ̀mí Mímọ́, a kì yóò dárí rẹ̀ jì í.
Yua n maadi o Joa Bijua po yaala n bia baa baa sugili, ama yua n sugi U Tienu Fuoma Yua kan baa sugili.
11 “Nígbà tí wọ́n bá sì mú yin wá sí Sinagọgu, àti síwájú àwọn olórí, àti àwọn aláṣẹ, ẹ má ṣe ṣàníyàn pé, báwo tàbí ohun kín ni ẹ̀yin yóò fèsì rẹ̀ tàbí kín ni ẹ̀yin ó wí.
Bi ya gedini li balimaama bangima diena nni, yaaka bi bujiaba kani, yaaka paatietoaba kani, ki baa jia leni yi ti buudi, yin da yagi mani yi yama leni yin baa maadi maama ki baa ga yi yula, leni yin baa yedi yaala kuli po,
12 Nítorí Ẹ̀mí Mímọ́ yóò kọ́ yín ní wákàtí kan náà ní ohun tí ó yẹ kí ẹ sọ.”
kelima lanyogunu lige U Tienu Fuoma yua baa bangi yi yin baa yedi yaala.”
13 Ọ̀kan nínú àwùjọ wí fún un pé, “Olùkọ́, sọ fún arákùnrin mi kí ó pín mi ní ogún.”
Ku niligu siiga niyendo den yedi Jesu: “Canbaa, waani n kpelo wan boagidi ti baa n ŋa ya faali ki teni nni n biinu.”
14 Ó sì wí fún un pé, “Ọkùnrin yìí, ta ni ó fi mí jẹ onídàájọ́ tàbí olùpíngún fún yín?”
Jesu den goa ki yedi o: “N danli ŋme dini nni li bali min jia yipo yi maama, ki boagidi yi faali?”
15 Ó sì wí fún wọn pé, “Kíyèsára kí o sì máa ṣọ́ra nítorí ojúkòkòrò: nítorí ìgbésí ayé ènìyàn kò dúró lé ọ̀pọ̀ ohun tí ó ní.”
O go den yedi bi niba kuli: “Fangi mani yi yula bonŋanla leni mi ŋalimanbuama, kelima o nilo miali ki ŋua leni o ŋalimano n yaba maama.”
16 Ó sì pa òwe kan fún wọn pé, “Ilẹ̀ ọkùnrin ọlọ́rọ̀ so ọ̀pọ̀lọpọ̀ èso.
Lani Jesu den pua ba mi kpanjama ki yedi: “O piado den ye ke o kuanu loni boncianla.
17 Ó sì rò nínú ara rẹ̀ pé, ‘Èmi ó ti ṣe, nítorí tí èmi kò ní ibi tí èmi ó gbé kó èso mi jọ sí.’
O den kpaagi ki yedi o pali nni: 'N baa tieni lede? Kelima mii pia min baa bili n kpaandi kuli naani.”
18 “Ó sì wí pé, ‘Èyí ni èmi ó ṣe: èmi ó wó àká mi palẹ̀, èmi ó sì kọ́ èyí tí ó tóbi; níbẹ̀ ni èmi ó gbé to gbogbo èso àti ọrọ̀ mi jọ sí.
O den goa ki yedi: 'N bani min baa tieni maama. N baa mumudi n buabuana ki goa ki maa ya n yaba ki cie, ki taani n kpaandi leni n piama kuli ki kuodi lienni.
19 Èmi ó sì wí fún ọkàn mi pé, ọkàn, ìwọ ní ọrọ̀ púpọ̀ tí a tò jọ fún ọ̀pọ̀ ọdún; sinmi, máa jẹ, máa mu, máa yọ̀.’
Lani n baayedi n yuli: A pia mi piama ke li kandi ya bina n yaba po, ya fuo ki di ki go ñu ki mangidi a pali.'
20 “Ṣùgbọ́n Ọlọ́run wí fún un pé, ‘Ìwọ aṣiwèrè, lóru yìí ni a ó béèrè ọkàn rẹ lọ́wọ́ rẹ; ǹjẹ́ ti ta ni nǹkan wọ̀nyí yóò ha ṣe, tí ìwọ ti pèsè sílẹ̀?’
Ama U Tienu den yedi o: O yanluodaano na dinla ya ñiagu liga n baa taa a naano ŋan bili yaala kuli baa tua ŋme ya yaala?”
21 “Bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó to ìṣúra jọ fún ara rẹ̀, tí kò sì ní ọrọ̀ lọ́dọ̀ Ọlọ́run.”
Jesu go den yedi: “Li tie yeni leni yua n taagi mi piama o yuceli po, ke o cima ki tie U Tienu po.”
22 Jesu sì wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Nítorí náà mo wí fún yín pé, ẹ má ṣe ṣe àníyàn nítorí ẹ̀mí yín pé, kín ni ẹ̀yin yóò jẹ tàbí nípa ara yin pe kín ni ẹyin o fi bora.
Li ya puoli jesu den yedi o ŋoadikaaba: Li tie lani yaapo ke n yedi yi, da yagi mani yi yama yi miana yema po, yin baa di yaala, leni yi gbannandi po yin baa yie yaala.
23 Ẹ̀mí sá à ju oúnjẹ lọ, ara sì ju aṣọ lọ.
Li miali cie mi jiema, ti gbannandi mo cie ti tiayiekaadi.
24 Ẹ kíyèsi àwọn ẹyẹ ìwò: wọn kì í fúnrúgbìn, bẹ́ẹ̀ ni wọn kì í kórè: wọn kò ní àká, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní abà, Ọlọ́run sá à ń bọ́ wọn: mélòó mélòó ni tí ẹ̀yin fi sàn ju ẹyẹ lọ!
Diidi mani a kankala, baa coagi, baa yendi, baa pia bilikaanu, baa pia buabuana. Leni lankuli U Tienu dindi ba. Ama yinba, yi pia mayuli boncianla ki cie ti bonyugiditi.
25 Ta ni nínú yín nípa àníyàn ṣíṣe tí ó lè fi ìgbọ̀nwọ́ kan kún ọjọ́ ayé rẹ̀?
Yi siiga ŋme yanyangidi n baa teni wan fidi ki foagidi o miali dana baa waanu?
26 Ǹjẹ́ bí ẹ̀yin kò ti lè ṣe èyí tí ó kéré bí eléyìí, èéṣe tí ẹ̀yin fi ń ṣàníyàn nítorí ìyókù?
Yi ya kan fidi ki tieni ya bonla n wa yeni, be yaapo ke yi bangi yaala n sieni kuli po.
27 “Ẹ kíyèsi àwọn lílì bí wọ́n ti ń dàgbà; wọn kì í ṣiṣẹ́, wọn kì í rànwú; ṣùgbọ́n kí èmi wí fún yín, a kò ṣe Solomoni pàápàá lọ́ṣọ̀ọ́ ní gbogbo ògo rẹ̀ tó ọ̀kan nínú ìwọ̀nyí.
Diidi mani mi moapuuma n ye maama, maa tuuni maa pia gaali, baa yeni, n yedi yi ke baa o bado Salomono leni o kpiagi ciandi kuli, waa den pundi mi siiga baa yenma n bobi maana.
28 Ǹjẹ́ bí Ọlọ́run bá wọ koríko igbó ní aṣọ tó bẹ́ẹ̀ èyí tí ó wà lónìí, tí a sì gbá a sínú iná lọ́la: mélòó mélòó ni yóò wọ̀ yín láṣọ, ẹ̀yin onígbàgbọ́ kékeré.
U Tienu ya bobindi ya muadi n ye ku muagu nni dinla ke bi baa fa ki taa ti ki cuoni mi fantama u fannu nni, laa pia kuli tama o baa yieni yi mo, yinba yaaba ya dandanli n ki yaba.
29 Kí ẹ má sì ṣe lé ohun tí ẹ ó jẹ, tàbí ohun tí ẹ ó mu, kí ẹ má sì ṣe ṣe àníyàn nínú ọkàn.
Da yagini mani yi yama leni yin baa di yaala lingina leni yin baa ñu yaala lingima.
30 Nítorí gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni àwọn orílẹ̀-èdè ayé ń wá kiri. Baba yín sì mọ̀ pé, ẹ̀yin ń fẹ́ nǹkan wọ̀nyí.
Kelima ya nibuoli n ki ŋua U Tienu ŋanduna nni kuli n kuandi bi yama laa bonla nni. Yi Baa bani ke laa bonla tie yipo tiladi.
31 Ṣùgbọ́n ẹ máa wá ìjọba Ọlọ́run, gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni a ó sì fi kún un fún yín.
Ama yin kpa lingi mani U Tieni diema nni lani laabonla kuli baa pugini yi po.
32 “Má bẹ̀rù, agbo kékeré, nítorí dídùn inú Baba yín ni láti fi ìjọba fún yín.
Da jie mani liba, fini ya yankulu n ki yaba, kelima li mani yi Baa wan pa yi mi diema.
33 Ẹ ta ohun tí ẹ̀yin ní, kí ẹ sì tọrẹ àánú kí ẹ sì pèsè àpò fún ara yín, tí kì í gbó, ìṣúra ní ọ̀run tí kì í tán, ní ibi tí olè kò lè súnmọ́, àti ibi tí kòkòrò kì í bà á jẹ́.
Kuadi mani yin pia yaala, ki pa a luoda yin kuadi ki ba ya ligi. Hanbi mani yi yula po tanpoli po ya ligiboagili n kan biidi leni ya ŋalimani n kaa pia gbenma, a sugida n kan nagini naankani, ti lulugidi mo n kan lugi ki bolini naankani.
34 Nítorí ní ibi tí ìṣúra yín gbé wà, níbẹ̀ ni ọkàn yín yóò gbé wà pẹ̀lú.
Kelima yi ŋalimani n ye naankani yi yantiana mo baa ye lankane.
35 “Ẹ di àmùrè yín, kí fìtílà yín sì máa jó.
Ñagini mani yi ciamu ku gbanñagidigu ki teni yi fidisanmu n ya co.
36 Kí ẹ̀yin tìkára yín dàbí ẹni tí ń retí olúwa wọn, nígbà tí òun ó padà ti ibi ìgbéyàwó dé, pé nígbà tí ó bá dé, tí ó sì kànkùn, kí wọn lè ṣí i sílẹ̀ fún un lọ́gán.
Yeni de, ya tie mani nani ya naacenba n gu bi canbaa n ña mi pocaanjiema po ki kpeni, ke o ya pundi ki yedi: 'luodi mani n po mani, 'ban luodi opo tontoni.
37 Ìbùkún ni fún àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ náà nígbà tí olúwa náà bá dé tí yóò bá wọn tí wọn ń ṣọ́nà; lóòótọ́ ni mo wí fún yín, yóò di ara rẹ̀ ní àmùrè yóò sì mú wọn jókòó láti jẹun, yóò sì jáde wá láti ṣe ìránṣẹ́ fún wọn.
Li pamanli ye leni ya naacenba ke bi canba kpeni ki sua ke bi nua ki gu o yeni. N yedi yi i moamoani ke o baa ñagini o ciaga, ki teni ban kali u saajekaanu kani, wan teni ba mi jiema.
38 Bí olúwa wọn bá sì dé nígbà ìṣọ́ kejì, tàbí tí ó sì dé nígbà ìṣọ́ kẹta, tí ó sì bá wọn bẹ́ẹ̀, ìbùkún ni fún àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ náà.
O ya kpeni o kootonmoa-kpialo, yaaka o kootonmoa-yuamo, ki sua ke bi nua ki gu, li pamanli baa ye leni ba.
39 Ṣùgbọ́n ẹ mọ èyí pé, baálé ilé ìbá mọ wákàtí tí olè yóò wá, òun ìbá máa ṣọ́nà, kì bá tí jẹ́ kí a já wọ inú ilé òun.
Yin bandi bonŋanla ke o diedaano ya bi bani o sugido n baa cua ya yogunu, o bi baa gu ki kan cedi o sugido n lugidi o dieli ki kua.
40 Nítorí náà, kí ẹ̀yin múra pẹ̀lú, nítorí Ọmọ Ènìyàn ń bọ̀ ní wákàtí tí ẹ̀yin kò nírètí.”
Yi moko n bogini ki ya gu kelima o Joa Bijua baa cua yin ki daani o ya yogunu.”
41 Peteru sì wí pé, “Olúwa, ìwọ pa òwe yìí fún wa, tàbí fún gbogbo ènìyàn?”
Pieli den yedi o: “N daano, a pua mi naa kpanjama tinba bebe po bi? Bi niba kuli po?”
42 Olúwa sì dáhùn wí pé, “Ta ni olóòtítọ́ àti ọlọ́gbọ́n ìríjú náà, tí olúwa rẹ̀ fi jẹ olórí agbo ilé rẹ̀, láti máa fi ìwọ̀n oúnjẹ wọ́n fún wọn ní àkókò?
O diedo den yedi: “Hme n tie ya tuonsoanjiidi-dugikoa n pia mi yanfuoma, ke o canbaa guuni o o niba ke wan ya tendi ba ya jiema n bili bipo?
43 Ìbùkún ni fún ọmọ ọ̀dọ̀ náà, nígbà tí olúwa rẹ̀ bá dé, tí yóò bá a kí ó máa ṣe bẹ́ẹ̀.
Li pamanli baa ye leni laa naacemo o canbaa ya kpeni ki sua ke o tiendi yeni.
44 Lóòótọ́ ni mo wí fún yín yóò fi jẹ olórí ohun gbogbo tí ó ní.
N waani yi i moamoani, o canbaa baa guuni o piama kuli.
45 Ṣùgbọ́n bí ọmọ ọ̀dọ̀ náà bá wí ní ọkàn rẹ̀, pé, ‘Olúwa mi fi ìgbà bíbọ̀ rẹ̀ falẹ̀!’ Tí ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í lu àwọn ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin tí ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í jẹ àti sí mu àmupara:
Ama laa naacemo ya yedi o pali nni: 'n canbaa waagi mi kpenma,' ki ji pua bi tuonsoanba bi jaba leni bi puoba kuli, ki di ki go ñu ŋali ki guodi,
46 Olúwa ọmọ ọ̀dọ̀ náà yóò dé ní ọjọ́ tí kò retí rẹ̀, àti ní wákàtí tí kò dábàá, yóò sì jẹ ẹ́ ní yà gidigidi, yóò sì yan ipò rẹ̀ pẹ̀lú àwọn aláìgbàgbọ́.
laa naacemo canbaa baa kpeni wan ki daani o ya daali leni wan ki faami ya yogunu. o baa teni ban waani o fala ŋali boncianla, ki gedi o ki ban taani leni yaaba n ki ŋua U Tienu.
47 “Àti ọmọ ọ̀dọ̀ náà, tí ó mọ ìfẹ́ olúwa rẹ̀, tí kò sì múra sílẹ̀, tí kò sì ṣe gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ rẹ̀, òun ni a ó nà púpọ̀.
Ya naacemo n bani o canbaa n bua wan ya tiedi yaala ki naa bogidi liba, kaa tiendi nani o canbaa n waani o maama, bi baa pua o ya puadi n yaba.
48 Ṣùgbọ́n èyí tí kò mọ̀, tí ó ṣe ohun tí ó yẹ sí lílù, òun ni a ó lù níwọ̀n. Nítorí ẹnikẹ́ni tí a fún ní púpọ̀, lọ́dọ̀ rẹ̀ ni a ó gbé béèrè púpọ̀: lọ́dọ̀ ẹni tí a bá gbé fi púpọ̀ sí, lọ́dọ̀ rẹ ni a ó gbé béèrè sí i.
De yua n kaa bani o canbaa n bua wan ya tiendi yaala, ki tiendi ya bonla n pundi ti puadi, o puadi kan ya yaba. Ban teni yua boncianla, bi baa bili ke wan guani boncianla. Ban piani yua ke li yaba bi baa bili ke wan guani yaala n yaba ki cie.
49 “Iná ni èmi wá láti sọ sí ayé; kín ni èmi sì ń fẹ́ bí kò ṣe kí iná náà ti jo!
N cua ki baa lu mi fantama ŋanduna nni. N bua ŋali bonŋanla ke li bi tuodi ki cuo no.
50 Ṣùgbọ́n èmi ní bamitiisi kan tí a ó fi bamitiisi mi; ara ti ń ni mí tó títí yóò fi parí!
Ama bi baa kpa batisi nni ya batisima n tie fala. N yama yagini boncianla ŋali lan baa tieni ki gbeni.
51 Ẹ̀yin ṣe bí àlàáfíà ni èmi fi sí ayé? Mo wí fún yín, bẹ́ẹ̀ kọ́; ṣùgbọ́n bí kò ṣe ìyapa.
Naani yi tama ke n cua ki baa tieni mi yanduanma ŋanduna nni bi? A-a, N cuani mi paadime.
52 Nítorí láti ìsinsin yìí lọ, ènìyàn márùn-ún yóò wà ní ilé kan náà tí a ó yà ní ipa, mẹ́ta sí méjì, àti méjì sí mẹ́ta.
Moala liiga niba muu dieyengu nni baa paadi leni bi yaba, niba taa baa koani leni niba lie, niba lie n koani leni niba taa.
53 A ó ya baba nípa sí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, àti ọmọ ọkùnrin sí baba; ìyá sí ọmọbìnrin, àti ọmọbìnrin sí ìyá rẹ̀, ìyá ọkọ sí ìyàwó ọmọ, àti ìyàwó ọmọ sí ìyá ọkọ rẹ̀.”
Bibaa baa koani leni o bijua, ki bonjaga mo n ya n ya koani leni o baa, binaa n koani leni o bisalo, ki bonpuoga mo n koani leni o naa. Yaanaa baa koani leni o biyuaga, ki biyuaga mo n koani leni o yaanaa.”
54 Ó sì wí fún ìjọ ènìyàn pẹ̀lú pé, “Nígbà tí ẹ̀yin bá rí àwọsánmọ̀ tí ó ṣú ní ìhà ìwọ̀-oòrùn, lọ́gán ni ẹ̀yin yóò sọ pé, ‘Ọ̀wààrà òjò ń bọ̀,’ a sì rí bẹ́ẹ̀.
Jesu go den yedi a nigola: “Yi ya laa ke ku tawaligu fii nintuali po, yi yen yedi tontoni ke ki taaga baa mi. Li yen tua yeni mo.
55 Nígbà tí afẹ́fẹ́ gúúsù bá ń fẹ́, ẹ̀yin á ní, ‘Oòrùn yóò mú,’ yóò sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Yi ya laa ke u faalu ñani niganu po, yi yen yedi ke ku wuligu baa tieni. Li moko yen tua yeni.
56 Ẹ̀yin àgàbàgebè! Ẹ̀yin le mòye ojú ọ̀run àti ti ayé. Èéha ti ṣe tí ẹ̀yin kò mọ àkókò yìí?
Yinba pala lie danba na, yi bani ki bundi tanpoli leni ki tinga sinankeeninba, be yaapo ke yi naa bani ki bundi ya yogunu n tie na ya sinankeeninba wani?
57 “Èéha ti ṣe tí ẹ̀yin tìkára yín kò fi ro ohun tí ó tọ́?
Be n teni ke yii kpaagi ki bandi yin baa tieni yaala lan ya tiegi?
58 Nígbà tí ìwọ bá bá ọ̀tá rẹ lọ sọ́dọ̀ onídàájọ́, rí i pé o bá a parí ọ̀rọ̀ ní ọ̀nà kí ó má ba à fà ọ́ fún adájọ́, adájọ́ a fi ọ́ lé ẹ̀ṣọ́ lọ́wọ́, òun a sì tì ọ́ sínú túbú.
Han yegi leni a koanginkoa ke yi caa li bujiali po ya yogunu, ŋan moandi ki dagidi leni o u sanu nni wan da gedini a o bujialo kani, o bujialo n da teni a sandalima, sandalima mo n da luoni a li kpaadidieli nni.
59 Kí èmi wí fún ọ, ìwọ kì yóò jáde kúrò níbẹ̀, títí ìwọ ó fi san ẹyọ owó kan tí ó kù!”
N yedi a, a kan ña lienni kali a ban pani ki gbeni, kaa sieni baa tanga.”

< Luke 12 >