< Job 17 >

1 “Ẹ̀mí mi bàjẹ́, ọjọ́ mi ni a ti gé kúrú, isà òkú dúró dè mí.
Mój oddech jest skażony, moje dni gasną, groby na mnie [czekają].
2 Nítòótọ́ àwọn ẹlẹ́yà wà lọ́dọ̀ mi, ojú mi sì tẹ̀mọ́ ìmúnibínú wọn.
Czy nie szydercy są przy mnie? Czy moje oko nie czuwa przez ich zniewagi?
3 “Fi fún mi Olúwa, ìlérí tí ìwọ fẹ́; ta ni yóò le ṣe ààbò fún mi?
Złóż więc zastaw za mnie u siebie. Któż jest ten, który za mnie poręczy?
4 Nítorí pé ìwọ ti sé wọ́n láyà kúrò nínú òye; nítorí náà ìwọ kì yóò gbé wọn lékè.
Ich serce bowiem ukryłeś przed zrozumieniem, dlatego [ich] nie wywyższysz.
5 Ẹni tí ó sọ ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn dídún fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ fún èrè, òun ni ojú àwọn ọmọ rẹ̀ yóò mú òfo.
Kto pochlebia przyjaciołom, tego dzieciom zgasną oczy.
6 “Ọlọ́run ti sọ mi di ẹni òwe fún àwọn ènìyàn; níwájú wọn ni mo dàbí ẹni ìtutọ́ sí ní ojú.
Uczynił mnie tematem przysłowia wśród ludzi i pośmiewiskiem przed nimi.
7 Ojú mí ṣú bàìbàì nítorí ìbìnújẹ́, gbogbo ẹ̀yà ara mi sì dàbí òjìji.
Moje oko zaćmiło się od smutku, a wszystkie moje członki są jak cień.
8 Àwọn olódodo yóò yanu sí èyí, ẹni aláìṣẹ̀ sì bínú sí àwọn àgàbàgebè.
Prawi zdumieją się nad tym, a niewinny powstanie przeciwko obłudnikowi.
9 Olódodo pẹ̀lú yóò di ọ̀nà rẹ̀ mú, àti ọlọ́wọ́ mímọ́ yóò máa lera síwájú.
Sprawiedliwy będzie trwał przy swojej drodze, a kto ma czyste ręce, nabierze siły.
10 “Ṣùgbọ́n bí ó ṣe ti gbogbo yín, ẹ yípadà, kí ẹ si tún padà nísinsin yìí; èmi kò le rí ọlọ́gbọ́n kan nínú yín.
Lecz wy wszyscy zawróćcie i przyjdźcie; bo mądrego wśród was nie znajduję.
11 Ọjọ́ tí èmi ti kọjá, ìrò mi ti fà yá, àní ìrò ọkàn mi.
Moje dni przeminęły, rozwiały się moje zamiary, myśli mego serca.
12 Àwọn ènìyàn wọ̀nyí ń ṣọ́ òru di ọ̀sán; wọ́n ní, ìmọ́lẹ̀ súnmọ́ ibi tí òkùnkùn dé.
Noc zamieniają w dzień, światłość skraca się z powodu ciemności.
13 Bí mo tilẹ̀ ní ìrètí, ipò òku ní ilé mi; mo ti tẹ́ ibùsùn mi sínú òkùnkùn. (Sheol h7585)
Gdybym czegoś oczekiwał, grób [będzie] moim domem, w ciemności rozłożyłem swoje posłanie. (Sheol h7585)
14 Èmi ti wí fún ìdíbàjẹ́ pé, ìwọ ni baba mi, àti fún kòkòrò pé, ìwọ ni ìyá mi àti arábìnrin mi,
Powiedziałem do zniszczenia: Jesteś moim ojcem, a robactwu: Moja matko i moja siostro.
15 ìrètí mi ha dà nísinsin yìí? Bí ó ṣe ti ìrètí mi ni, ta ni yóò rí i?
Gdzie jest więc teraz moja nadzieja? Kto zobaczy moją nadzieję?
16 Yóò sọ̀kalẹ̀ lọ sínú ipò òkú, nígbà tí a jùmọ̀ sinmi pọ̀ nínú erùpẹ̀ ilẹ̀?” (Sheol h7585)
Zstąpią do zasuw grobu, gdy razem odpoczniemy w prochu. (Sheol h7585)

< Job 17 >