< 2 Samuel 19 >

1 A sì rò fún Joabu pe, “Wò ó, ọba ń sọkún, ó sì ń gbààwẹ̀ fún Absalomu.”
Nake Joabu akĩĩrwo atĩrĩ, “Mũthamaki nĩararĩra agĩcakayagĩra Abisalomu.”
2 Ìṣẹ́gun ọjọ́ náà sì di àwẹ̀ fún gbogbo àwọn ènìyàn náà, nítorí àwọn ènìyàn náà gbọ́ ní ọjọ́ náà bí inú ọba ti bàjẹ́ nítorí ọmọ rẹ̀.
Naguo ũhootani wa mũthenya ũcio wa mbũtũ cia ita ciothe ũkĩgarũrũka, ũgĩtuĩka macakaya, tondũ mũthenya ũcio mbũtũ cia ita nĩciaiguire gũkĩĩrwo atĩrĩ, “Mũthamaki arĩ na kĩeha nĩ ũndũ wa mũriũ.”
3 Àwọn ènìyàn náà sì yọ́ lọ sí ìlú ní ọjọ́ náà gẹ́gẹ́ bí àwọn bí ènìyàn tí a dójútì ṣe máa ń yọ́ lọ nígbà tí wọ́n bá sá lójú ìjà.
Mũthenya ũcio andũ magĩcooka itũũra-inĩ inene na hitho, o ta ũrĩa andũ macookaga na hitho maconokete rĩrĩa moorĩte kuuma mbaara-inĩ.
4 Ọba sì bo ojú rẹ̀, ọba sì kígbe ní ohùn rara pé, “Á à! Ọmọ mi Absalomu! Absalomu ọmọ mi, ọmọ mi!”
Nake mũthamaki akĩhumbĩra ũthiũ, akĩrĩra na mũgambo mũnene akiugaga atĩrĩ, “Ũũi Abisalomu, mũrũ wakwa! Ũũi Abisalomu, mũrũ wakwa, mũrũ wakwa!”
5 Joabu sì wọ inú ilé tọ ọba lọ, ó sì wí pé, “Ìwọ dójúti gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ lónìí, àwọn tí ó gba ẹ̀mí rẹ̀ là lónìí, àti ẹ̀mí àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, àti ti àwọn ọmọbìnrin rẹ̀, àti àwọn aya rẹ̀, àti ẹ̀mí àwọn obìnrin rẹ.
Hĩndĩ ĩyo Joabu agĩtoonya nyũmba kũrĩ mũthamaki, akĩmwĩra atĩrĩ, “Ũmũthĩ nĩũconorithĩtie andũ aku othe, arĩa marĩkĩtie kũhonokia muoyo waku, na mĩoyo ya ariũ aku na ya airĩtu aku, na mĩoyo ya atumia aku o na ya thuriya ciaku.
6 Nítorí pé ìwọ fẹ́ àwọn ọ̀tá rẹ, ìwọ sì kórìíra àwọn ọ̀rẹ́ rẹ. Nítorí tí ìwọ wí lónìí pé, Ìwọ kò náání àwọn ọmọ ọba tàbí àwọn ìránṣẹ́; èmi sì rí lónìí pé, ìbá ṣe pé Absalomu wà láààyè, kí gbogbo wa sì kú lónìí, ǹjẹ́ ìbá dùn mọ́ ọ gidigidi.
Wee wendete arĩa magũthũire, na ũkamena arĩa makwendete. Ũmũthĩ nĩwonanĩtie biũ atĩ ndũrĩ bata na anene a mbũtũ cia ita o na andũ ao. Niĩ nguona atĩ wee gĩkeno gĩaku kĩngĩrĩ rĩrĩa Abisalomu angĩrĩ muoyo ũmũthĩ na ithuothe tũkorwo tũkuĩte.
7 Sì dìde nísinsin yìí, lọ, kí o sì sọ̀rọ̀ ìtùnú fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ, nítorí pé èmi fi Olúwa búra, bí ìwọ kò bá lọ, ẹnìkan kì yóò bá ọ dúró ni alẹ́ yìí, èyí ni yóò sì burú fún ọ ju gbogbo ibi tí ojú rẹ ti ń rí láti ìgbà èwe rẹ wá títí ó fi di ìsinsin yìí.”
Rĩu ũkĩra ũthiĩ ũkoomĩrĩrie andũ aku ũmekĩre hinya. Niĩ ngwĩhĩta na rĩĩtwa rĩa Jehova atĩ aakorwo ndũkuuma ũthiĩ gũtanatuka, gũtirĩ mũndũ o na ũmwe ũgũkorwo mwena waku. Ũndũ ũyũ ũgũtuĩka mũũru kũrĩ we gũkĩra maũndũ mothe mooru marĩa managũkora kuuma ũrĩ mũnini nginya rĩu.”
8 Ọba sì dìde, ó sì jókòó ní ẹnu-ọ̀nà, wọ́n sì wí fún gbogbo àwọn ènìyàn náà pé, “Wò ó, ọba jókòó ní ẹnu-ọ̀nà.” Gbogbo ènìyàn sì wá sí iwájú ọba. Nítorí pé, Israẹli ti sá, olúkúlùkù sí àgọ́ rẹ̀.
Nĩ ũndũ ũcio mũthamaki agĩũkĩra, agĩikarĩra gĩtĩ gĩake kĩhingo-inĩ. Hĩndĩ ĩrĩa andũ meerirwo atĩrĩ, “Mũthamaki aikarĩte kĩhingo-inĩ,” othe magĩũka mbere yake. Na rĩrĩ, andũ a Isiraeli nĩmoorĩte magacooka kwao mĩciĩ.
9 Gbogbo àwọn ènìyàn náà sì ń bà ara wọn jà nínú gbogbo ẹ̀yà Israẹli, pé, “Ọba ti gbà wá là lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa, ó sì ti gbà wá kúrò lọ́wọ́ àwọn Filistini; òun sì wá sá kúrò ní ìlú nítorí Absalomu.
Mĩhĩrĩga-inĩ yothe ya Isiraeli, andũ othe maakararanagia makoiga atĩrĩ, “Mũthamaki nĩwe watũkũũrire kuuma guoko-inĩ gwa thũ ciitũ; nĩwe watũhonokirie kuuma guoko-inĩ kwa Afilisti. No rĩu nĩorĩte akoima bũrũri-inĩ akĩũrĩra Abisalomu;
10 Absalomu, tí àwa fi jẹ ọba lórí wa sì kú ní ogun, ǹjẹ́ èéṣe tí ẹ̀yin fi dákẹ́ tí ẹ̀yin kò sì sọ̀rọ̀ kan láti mú ọba padà wá?”
nake Abisalomu ũrĩa twaitĩrĩirie maguta atũthamakĩre-rĩ, nĩakuĩrĩire mbaara-inĩ. Nĩ ũndũ ũcio mwagĩte kwaria ũhoro wa gũcookia mũthamaki nĩkĩ?”
11 Dafidi ọba sì ránṣẹ́ sí Sadoku, àti sí Abiatari àwọn àlùfáà pé, “Sọ fún àwọn àgbàgbà Juda, pé, ‘Èéṣe tí ẹ̀yin fi kẹ́yìn láti mú ọba padà wá sí ilé rẹ̀? Ọ̀rọ̀ gbogbo Israẹli sì ti dé ọ̀dọ̀ ọba àní ní ilé rẹ̀.
Mũthamaki Daudi nĩatũmanire kũrĩ Zadoku na Abiatharu, athĩnjĩri-Ngai, makeerwo atĩrĩ, “Ũriai athuuri a Juda atĩrĩ, ‘Nĩ kĩĩ gĩgũtũma mũrigie thuutha harĩ gũcookia mũthamaki nyũmba-inĩ yake ya ũthamaki, kuona atĩ ũrĩa kũraario Isiraeli guothe nĩgũkinyĩire mũthamaki kũrĩa aikaraga?
12 Ẹ̀yin ni ara mi, ẹ̀yin ni egungun mi, àti ẹran-ara mi: èéṣì ti ṣe tí ẹ̀yin fi kẹ́yìn láti mú ọba padà wá.’
Inyuĩ mũrĩ ariũ a baba, tũrĩ a mũthiimo ũmwe, na thakame ĩmwe. Nĩ kĩĩ kĩngĩtũma mũtuĩke a kũrigia thuutha kũinũkia mũthamaki?’
13 Kí ẹ̀yin sì wí fún Amasa pé, ‘Egungun àti ẹran-ara mi kọ́ ni ìwọ jẹ́ bí? Kí Ọlọ́run ó ṣe bẹ́ẹ̀ sí mi àti jù bẹ́ẹ̀ lọ pẹ̀lú, bí ìwọ kò ba ṣe olórí ogun níwájú mi títí, ní ipò Joabu.’”
Ningĩ mwĩre Amasa atĩrĩ, ‘Githĩ wee ndũrĩ wa mũthiimo wakwa, na thakame yakwa? Ngai arothũũra o na anjĩke ũũru makĩria, angĩkorwo kuuma rĩu gũthiĩ na mbere wee tiwe ũgũtuĩka mũnene wa mbũtũ ciakwa cia ita ithenya rĩa Joabu.’”
14 Òun sì yí gbogbo àwọn ọkùnrin Juda lọ́kàn padà àní bí ọkàn ènìyàn kan; wọ́n sì ránṣẹ́ sí ọba, pé, “Ìwọ padà àti gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ.”
Nake mũthamaki akĩguucĩrĩria ngoro cia andũ othe a Juda ta ciarĩ ngoro ya mũndũ ũmwe. Nao magĩtũmana kũrĩ mũthamaki, makiuga atĩrĩ, “Cooka, wee hamwe na andũ aku othe.”
15 Ọba sì padà, o sì wá sí odò Jordani. Juda sì wá sí Gilgali láti lọ pàdé ọba, àti láti mú ọba kọjá odò Jordani.
Hĩndĩ ĩyo mũthamaki agĩcooka agĩthiĩ agĩkinya Jorodani. Na rĩrĩ, andũ a Juda nĩmookĩte Giligali nĩguo matũnge mũthamaki mamũringie Rũũĩ rwa Jorodani.
16 Ṣimei ọmọ Gera, ará Benjamini ti Bahurimu, ó yára ó sì bá àwọn ọkùnrin Juda sọ̀kalẹ̀ láti pàdé Dafidi ọba.
Nake Shimei mũrũ wa Gera, Mũbenjamini kuuma Bahurimu, agĩikũrũka na ihenya marĩ na andũ a Juda nĩguo magatũnge Mũthamaki Daudi.
17 Ẹgbẹ̀rún ọmọkùnrin sì wà lọ́dọ̀ rẹ̀ nínú àwọn ọmọkùnrin Benjamini, Ṣiba ìránṣẹ́ ilé Saulu, àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún àti ogún ìránṣẹ́ sì pẹ̀lú rẹ̀; wọ́n sì gòkè odò Jordani ṣáájú ọba.
Nake aarĩ na andũ a Benjamini ngiri ĩmwe, o hamwe na Ziba ndungata ya mũciĩ wa Saũlũ, na ariũ ake ikũmi na atano, na ndungata mĩrongo ĩĩrĩ. Nao makĩhanyũka nginya Rũũĩ rwa Jorodani harĩa mũthamaki aarĩ.
18 Ọkọ̀ èrò kan ti rékọjá láti kó àwọn ènìyàn ilé ọba sí òkè, àti láti ṣe èyí tí ó tọ́ lójú rẹ̀. Ṣimei ọmọ Gera wólẹ̀. Ó sì dojúbolẹ̀ níwájú ọba, bí ó tí gòkè odò Jordani.
Makĩringĩra iriũko-inĩ nĩguo maringie andũ a nyũmba ya mũthamaki na meeke o ũrĩa angĩenda. Hĩndĩ ĩrĩa Shimei mũrũ wa Gera aaringire Rũũĩ rwa Jorodani akĩĩgũithia thĩ mbere ya mũthamaki,
19 Ó sì wí fún ọba pé, “Kí olúwa mi ó má ṣe ka ẹ̀ṣẹ̀ sí mi lọ́rùn, má sì ṣe rántí àfojúdi tí ìránṣẹ́ rẹ̀ ṣe ni ọjọ́ tí olúwa mi ọba jáde ní Jerusalẹmu, kí ọba má sì fi sí inú.
na akĩmwĩra atĩrĩ, “Mwathi wakwa nĩ atige kũndua mwĩhia. Tiga kũririkana ũrĩa ndungata yaku yekire mahĩtia mũthenya ũrĩa mũthamaki mwathi wakwa oimire Jerusalemu. Mũthamaki nĩatige kũiga ũhoro ũcio meciiria-inĩ make.
20 Nítorí pé ìránṣẹ́ rẹ mọ̀ pé èmi ti ṣẹ̀; sì wò ó, mo wá lónìí yìí, ẹni àkọ́kọ́ ní gbogbo ìdílé Josẹfu tí yóò sọ̀kalẹ̀ wá pàdé olúwa mi ọba.”
Nĩgũkorwo niĩ ndungata yaku nĩnjũũĩ atĩ nĩnjĩhĩtie, no ũmũthĩ nĩndoka haha ndĩ mũndũ wa mbere wa nyũmba yothe ya andũ a Jusufu; ndaikũrũka njũke ndũnge mũthamaki mwathi wakwa.”
21 Ṣùgbọ́n Abiṣai ọmọ Seruiah dáhùn ó sì wí pé, “Kò ha tọ́ kí a pa Ṣimei nítorí èyí? Nítorí pé òun ti bú ẹni àmì òróró Olúwa.”
Ningĩ Abishai mũrũ wa Zeruia akiuga atĩrĩ, “Githĩ Shimei ndagĩrĩire nĩ kũũragwo nĩ ũndũ wa ũrĩa ekĩte? Nĩarumire mũitĩrĩrie maguta wa Jehova.”
22 Dafidi sì wí pé, “Kí ni èmi ní ṣe pẹ̀lú yín, ẹ̀yin ọmọ Seruiah tí ẹ dàbí ọ̀tá fún mi lónìí? A ha lè pa ènìyàn kan lónìí ní Israẹli? Tàbí èmi kò ha mọ̀ pé lónìí èmi ni ọba Israẹli.”
Nake Daudi agĩcookia atĩrĩ, “Tũnyiitanĩire ũndũ ũrĩkũ na inyuĩ, inyuĩ ariũ a Zeruia? Ũmũthĩ nĩguo mũgũtuĩka thũ ciakwa! No kũhoteke mũndũ o na ũrĩkũ ooragwo thĩinĩ wa Isiraeli ũmũthĩ? Githĩ niĩ ndikĩũĩ atĩ ũmũthĩ nĩ niĩ mũthamaki wa Isiraeli?”
23 Ọba sì wí fún Ṣimei pé, “Ìwọ kì yóò kú!” Ọba sì búra fún un.
Nĩ ũndũ ũcio mũthamaki akĩĩra Shimei atĩrĩ, “Wee ndũgũkua.” Nake mũthamaki akĩmũhe ũhoro ũcio na mwĩhĩtwa.
24 Mefiboṣeti ọmọ Saulu sì sọ̀kalẹ̀ láti wá pàdé ọba, kò wẹ ẹsẹ̀ rẹ̀, kò sí tọ́ irùngbọ̀n rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò sì fọ aṣọ rẹ̀ láti ọjọ́ tí ọba ti jáde títí ó fi di ọjọ́ tí ó fi padà ní àlàáfíà.
Na rĩrĩ, Mefiboshethu, mwana wa mũriũ wa Saũlũ, o nake nĩaikũrũkire agĩthiĩ gũtũnga mũthamaki. Nake ndethambĩte magũrũ kana akenja nderu, o na kana akahũũra nguo ciake kuuma mũthenya ũrĩa mũthamaki aathiire nginya mũthenya ũrĩa aacookire arĩ na thayũ.
25 Nígbà tí òun sì wá sí Jerusalẹmu láti pàdé ọba, ọba sì wí fún un pé, “Èéṣe tí ìwọ kò fi bá mi lọ, Mefiboṣeti?”
Rĩrĩa ooimire Jerusalemu agatũnge mũthamaki, mũthamaki akĩmũũria atĩrĩ, “Mefiboshethu, nĩ kĩĩ kĩagiririe ũthiĩ na niĩ?”
26 Òun sì dáhùn wí pé, “Olúwa mi, ọba, ìránṣẹ́ mi ni ó tàn mí, nítorí ìránṣẹ́ rẹ wí fún un pé, ‘Di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ní gàárì fún mi èmi ó gùn ún, èmi ó sì tọ ọba lọ.’ Nítorí tí ìránṣẹ́ rẹ yarọ.
Nake akiuga atĩrĩ, “Mũthamaki mwathi wakwa, nĩgũkorwo niĩ ndungata yaku ndĩ mwonju, ‘Ndoigire atĩrĩ, nĩngũigĩrĩra ndigiri yakwa matandĩko na ndĩmĩhaice, nĩguo hote gũthiĩ na mũthamaki’. No Ziba ndungata yakwa akĩngunyanĩra.
27 Ó sì sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ sí ìránṣẹ́ rẹ, fún olúwa mi ọba, ṣùgbọ́n bí angẹli Ọlọ́run ni olúwa mi ọba rí, nítorí náà ṣe èyí tí ó dára lójú rẹ.
Na nĩacambĩtie ndungata yaku kũrĩ mũthamaki mwathi wakwa. Mwathi wakwa mũthamaki ahaana ta mũraika wa Ngai; nĩ ũndũ ũcio ĩka ũrĩa ũkuona kwagĩrĩire.
28 Nítorí pé gbogbo ilé baba mi bí òkú ènìyàn ni wọ́n sá à rí níwájú olúwa mi ọba, ìwọ sì fi ipò fún ìránṣẹ́ rẹ láàrín àwọn tí ó ń jẹun ní ibi oúnjẹ. Nítorí náà àre kín ni èmi ní tí èmi yóò fi máa ké pe ọba síbẹ̀.”
Njiaro ciothe cia guka ciagĩrĩirwo nĩ kũũragwo nĩ mũthamaki mwathi wakwa. No wee nĩwaheire ndungata yaku handũ na arĩa marĩĩagĩra metha-inĩ yaku. Nĩ ũndũ ũcio ndĩ na kĩhooto kĩrĩkũ gĩa gũgũkaĩra rĩngĩ mũthamaki wakwa?”
29 Ọba sì wí fún un pé, “Èéṣe tí ìwọ fi ń sọ ọ̀ràn ara rẹ fún mi èmi sá à ti wí pé, kí ìwọ àti Ṣiba pín ilẹ̀ náà.”
Mũthamaki akĩmwĩra atĩrĩ, “Nĩ kĩĩ kĩngĩtũma warie makĩria ma ũguo? Ndaathana atĩ wee na Ziba mũgayane mũgũnda.”
30 Mefiboṣeti sì wí fún ọba pé, “Jẹ́ kí ó mú gbogbo rẹ̀, kí olúwa mi ọba sá à ti padà bọ̀ wá ilé rẹ̀ ni àlàáfíà.”
Mefiboshethu akĩĩra mũthamaki atĩrĩ, “Reke oe mĩgũnda yothe, kuona atĩ wee mwathi wakwa nĩũcookete mũciĩ na thayũ.”
31 Barsillai ará Gileadi sì sọ̀kalẹ̀ láti Rogelimu wá, ó sì bá ọba gòkè odò Jordani, láti ṣe ìkẹ́ rẹ̀ sí ìkọjá odò Jordani.
Ningĩ Barizilai, ũrĩa Mũgileadi agĩikũrũka kuuma Rogelimu akaringe Rũũĩ rwa Jorodani me hamwe na mũthamaki, na amumagarie njĩra-inĩ ya kuuma kũu.
32 Barsillai sì jẹ́ arúgbó ọkùnrin gidigidi, ẹni ogbó ọgọ́rin ọdún sì ni, ó sì pèsè ohun jíjẹ fún ọba nígbà tí ó ti wà ní Mahanaimu; nítorí pé ọkùnrin ọlọ́lá ni òun ń ṣe.
Na rĩrĩ, Barizilai aarĩ mũthuuri mũkũrũ mũno wa mĩaka mĩrongo ĩnana. Nĩwe waheaga mũthamaki irio hĩndĩ ĩrĩa aikarĩte Mahanaimu, tondũ aarĩ mũndũ mũtongu mũno.
33 Ọba sì wí fún Barsillai pé, “Ìwọ wá bá mi gòkè odò, èmi ó sì máa pèsè fún ọ ní Jerusalẹmu.”
Nake mũthamaki akĩĩra Barizilai atĩrĩ, “Nĩtũringe mũrĩmo nawe, tũthiĩ ũikare hamwe na niĩ Jerusalemu, na nĩndĩrĩkũheaga irio.”
34 Barsillai sì wí fún ọba pé, “Ọjọ́ mélòó ni ọdún ẹ̀mí mi kù, tí èmi ó fi bá ọba gòkè lọ sí Jerusalẹmu.
Nowe Barizilai agĩcookeria mũthamaki atĩrĩ, “Nĩ mĩaka ĩngĩ ĩigana atĩa niĩ ngũtũũra muoyo nĩguo nyambate thiĩ Jerusalemu hamwe na mũthamaki?
35 Ẹni ogbó ọgọ́rin ọdún sá à ni èmi lónìí, ǹjẹ́ èmi mọ ìyàtọ̀ nínú rere àti búburú? Ǹjẹ́ ìránṣẹ́ rẹ le mọ adùn ohun tí òun ń jẹ tàbí ohun ti òun ń mu bí? Èmi tún lè mọ adùn ohùn àwọn ọkùnrin tí ń kọrin àti àwọn obìnrin tí ń kọrin bí, ǹjẹ́ nítorí kín ni ìránṣẹ́ rẹ yóò ṣe jẹ́ ìyọnu síbẹ̀ fún olúwa mi ọba.
Rĩu ndĩ na ũkũrũ wa mĩaka mĩrongo ĩnana. No menye ũtiganu wa ũndũ mwega na mũũru? Ndungata yaku yahota gũcama kĩrĩa ĩrarĩa na kĩrĩa ĩranyua? No hote kũigua mĩgambo ya arũme na ya andũ-a-nja makĩina? Nĩ kĩĩ kĩngĩtũma ndungata yaku ĩtuĩke mũrigo ũngĩ kũrĩ mũthamaki mwathi wakwa?
36 Ìránṣẹ́ rẹ yóò sì sin ọba lọ díẹ̀ gòkè odò Jordani; èéṣì ṣe tí ọba yóò fi san ẹ̀san yìí fún mi.
Ndungata yaku nĩĩkũringa Rũũĩ rwa Jorodani hamwe na mũthamaki handũ ha itĩĩna inini, no nĩ kĩĩ kĩngĩtũma mũthamaki andĩhe niĩ na njĩra ĩyo?
37 Èmi bẹ̀ ọ́, jẹ́ kí ìránṣẹ́ rẹ padà, èmi ó sì kú ní ìlú mi, a ó sì sin mí ní ibojì baba àti ìyá mi. Sì wo Kimhamu ìránṣẹ́ rẹ, yóò bá olúwa mi ọba gòkè; ìwọ ó sì ṣe ohun tí ó bá tọ́ lójú rẹ fún un.”
Reke ndungata yaku ĩcooke, nĩgeetha ngaakuĩra itũũra-inĩ rĩakwa hakuhĩ na mbĩrĩra ya baba na maitũ. No rĩrĩ, ndungata yaku Kimuhamu nĩĩringe hamwe na mũthamaki mwathi wakwa. Mĩĩke o ũrĩa ũkuona kwagĩrĩire.”
38 Ọba sì dáhùn wí pé, “Kimhamu yóò bá mi gòkè, èmi ó sì ṣe èyí tí ó tọ́ lójú rẹ̀ fún un; ohunkóhun tí ìwọ bá sì béèrè lọ́wọ́ mi, èmi ó ṣe é fún ọ.”
Mũthamaki akiuga atĩrĩ, “Kimuhamu nĩekũringa hamwe na niĩ, na nĩngũmwĩka o ũrĩa ũngĩona kwagĩrĩire. Na ũrĩa wothe ũngĩenda kuuma kũrĩ niĩ nĩ ngũgwĩkĩra.”
39 Gbogbo àwọn ènìyàn sì gòkè odò Jordani ọba sì gòkè; ọba sì fi ẹnu ko Barsillai lẹ́nu, ó sì súre fún un; òun sì padà sí ilé rẹ̀.
Nĩ ũndũ ũcio andũ othe makĩringa Rũũĩ rwa Jorodani, nake mũthamaki agĩcooka akĩringa. Mũthamaki akĩmumunya Barizilai na akĩmũrathima, nake Barizilai agĩcooka gwake mũciĩ.
40 Ọba sì ń lọ́ sí Gilgali, Kimhamu sì ń bà a lọ, gbogbo àwọn ènìyàn Juda sì ń ṣe ìkẹ́ ọba, àti ààbọ̀ àwọn ènìyàn Israẹli.
Rĩrĩa mũthamaki aaringire mũrĩmo agĩkinya Giligali, Kimuhamu akĩringa hamwe nake. Nacio mbũtũ ciothe cia ita cia Juda na nuthu ya mbũtũ cia ita cia Isiraeli ikĩringia mũthamaki.
41 Sì wò ó, gbogbo àwọn ọkùnrin Israẹli sì tọ ọba wá, wọ́n sì wí fún ọba pé, “Èéṣe tí àwọn arákùnrin wa àwọn ọkùnrin Juda fi jí ọ kúrò, tí wọ́n sì fi mú ọba àti àwọn ará ilé rẹ̀ gòkè odò Jordani, àti gbogbo àwọn ènìyàn Dafidi pẹ̀lú rẹ?”
Thuutha wa kahinda kanini andũ othe a Isiraeli nĩmookaga kũrĩ mũthamaki makamwĩra atĩrĩ, “Nĩ kĩĩ gĩatũmire ariũ a baba, andũ a Juda, matũtunye mũthamaki na wara, na mamũcookie nyũmba yake kuuma mũrĩmo wa Jorodani, hamwe na andũ ake othe?”
42 Gbogbo ọkùnrin Juda sì dá àwọn ọkùnrin Israẹli lóhùn pé, “Nítorí pé ọba bá wa tan ni; èéṣe tí ẹ̀yin fi bínú nítorí ọ̀ràn yìí? Àwa jẹ nínú oúnjẹ ọba rárá bí? Tàbí ó fi ẹ̀bùn kan fún wa bí?”
Andũ othe a Juda magĩcookeria andũ a Isiraeli atĩrĩ, “Twekire ũguo tondũ mũthamaki nĩ wa nyũmba iitũ. Nĩ kĩĩ gĩgũtũma mũrakario nĩ ũhoro ũcio? Nĩ irio tũrĩĩte cia mũthamaki? Nĩ harĩ kĩndũ twĩyoeire ithuĩ ene?”
43 Àwọn ọkùnrin Israẹli náà sì dá àwọn ọkùnrin Juda lóhùn pé, “Àwa ní ipá mẹ́wàá nínú ọba, àwa sì ní nínú Dafidi jù yín lọ, èéṣì ṣe tí ẹ̀yin kò fi kà wá sí, tí ìmọ̀ wa kò fi ṣáájú láti mú ọba wa padà?” Ọ̀rọ̀ àwọn ọkùnrin Juda sì le ju ọ̀rọ̀ àwọn ọkùnrin Israẹli.
Ningĩ andũ a Isiraeli magĩcookeria andũ a Juda atĩrĩ, “Ithuĩ tũrĩ na icunjĩ ikũmi kũrĩ mũthamaki, na hamwe na ũguo-rĩ, tũrĩ na kĩhooto gĩa gũtuĩka a Daudi gũkĩra inyuĩ. Nĩ ũndũ ũcio nĩ kĩĩ gĩgũtũma mũtũmene? Githĩ ti ithuĩ twarĩ a mbere kwaria ũhoro wa gũcookia mũthamaki witũ?” No andũ a Juda magĩcookia marĩ na ũũru mũingĩ mũno o na gũkĩra andũ a Isiraeli.

< 2 Samuel 19 >