< 2 Chronicles 1 >

1 Solomoni ọmọ Dafidi fìdí ara rẹ̀ múlẹ̀ ṣinṣin lórí ìjọba rẹ̀. Nítorí tí Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ wà pẹ̀lú u rẹ̀, ó sì jẹ́ kí ó ga lọ́pọ̀lọ́pọ̀.
U A paa ia Solomona, ke keiki a Davida, kona aupuni, a me ia pu o Iehova kona Akua, a hookiekie nui mai la ia ia.
2 Nígbà náà, Solomoni bá gbogbo Israẹli sọ̀rọ̀ sí àwọn alákòóso ẹgbẹẹgbẹ̀rún àti àwọn alákòóso ọ̀rọ̀ọ̀rún, sí àwọn adájọ́ àti sí gbogbo àwọn olórí Israẹli, àwọn olórí ìdílé
Olelo aku la o Solomona i ka Iseraela a pau, i na luna o na tausani a me ko na haneri, a me na lunakanawai, a me kela luna keia luna o ka Iseraela a pau, ka poe koikoi o na makua.
3 pẹ̀lú Solomoni, àti gbogbo àpéjọ lọ sí ibi gíga ní Gibeoni, nítorí àgọ́ Ọlọ́run fún pípàdé wà níbẹ̀, tí Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti pa ní aginjù.
A hele aku la o Solomona, a me ia pu ka ahakanaka a pau, i kahi kiekie, aia no ma Gibeona; no ka mea, malaila no ka halelewa o ke anainakanaka o ke Akua, ka mea a Mose ke kauwa a Iehova i hana'i ma ka waonahele.
4 Nísinsin yìí, Dafidi ti gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run wá láti Kiriati-Jearimu sí ibi tí ó ti pèsè fún un, nítorí ó ti kọ́ àgọ́ fún un ni Jerusalẹmu.
Aka, o ka pahu berita o ke Akua, ua lawe mai o Davida mai Kiriataiearima aku, i kahi ana i kukulu ai no ia mea; no ka mea, ua kukulu no ia i halelewa no ia mea ma Ierusalema.
5 Ṣùgbọ́n pẹpẹ idẹ tí Besaleli ọmọ Uri, ọmọ Huri, ti ṣe wà ní Gibeoni níwájú àgọ́ Olúwa, bẹ́ẹ̀ ni Solomoni àti gbogbo àpéjọ béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ níbẹ̀.
A o ke kuahu keleawe ka mea a Bezaleela ke keiki a Uri, ke keiki a Hura, i hana'i, malaila ia imua o ka noho o Iehova. A imi pinepine o Solomona a me ke anainakanaka ilaila.
6 Solomoni gòkè lọ sí ibi pẹpẹ idẹ níwájú Olúwa ní ibi àgọ́ ìpàdé, ó sì rú ẹgbẹ̀rún ẹbọ sísun lórí rẹ̀.
A mohai aku la o Solomona malaila maluna o ke kuahu keleawe imua o Iehova, aia ma ka halelewa o ke anainakanaka. A mohai aku la oi'a maluna olaila, i na mohaikuni hookahi tausani.
7 Ní òru ọjọ́ náà, Ọlọ́run farahàn Solomoni, ó sì wí fún un pé, “Béèrè fún ohunkóhun tí ìwọ bá fẹ́ kí n fún ọ.”
Ia po no ikea mai la ke Akua e Solomona, olelo mai ia ia, E noi mai oe i ka mea a'u e haawi aku ai ia oe.
8 Solomoni dá Ọlọ́run lóhùn pé, “Ìwọ ti fi àánú ńlá han Dafidi baba mi, ìwọ sì ti fi mí jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
I aku la o Solomona i ke Akua, Ua hoike mai oe i ke aloha nui ia Davida i ko'u makuakane, a hoalii oe ia'u mahope ona.
9 Nísinsin yìí Olúwa Ọlọ́run, jẹ́ kí ìlérí rẹ sí baba à mi Dafidi wá sí ìmúṣẹ, nítorí ìwọ ti fi mí jẹ ọba lórí àwọn ènìyàn tí ó pọ̀ bí erùpẹ̀ ilẹ̀.
Ano hoi, e Iehova, e ke Akua e, e hooko mai i ka olelo au i olelo mai ai ia Davida, i ko'u makuakane; no ka mea, nau no i hoalii mai ia'u maluna o ka poe kanaka i like ka nui me na huna lepo o ka honua.
10 Fún mi ní ọgbọ́n àti ìmọ̀, kí èmi kí ó lè máa wọ ilé kí ń sì máa jáde níwájú ènìyàn wọ̀nyí, nítorí ta ni ó le è ṣàkóso àwọn ènìyàn rẹ tí ó pọ̀ yanturu wọ̀nyí?”
Ano, e haawi mai ia'u i ka naauao, a me ke akamai i puka aku au iwaho imua o keia lahuikanaka, a komo mai no hoi, no ka mea, ia wai la e hiki ai ke malama i keia poe kanaka nui ou?
11 Ọlọ́run wí fún Solomoni pé, “Níwọ́n ìgbà tí ó jẹ́ pé ìfẹ́ ọkàn rẹ nìyí, tí ìwọ kò sì béèrè, fún ọrọ̀, ọlá tàbí ọ̀wọ̀, tàbí fún ikú àwọn ọ̀tá rẹ, àti nígbà tí ìwọ kò ti béèrè fún ẹ̀mí gígùn, ṣùgbọ́n tí ìwọ béèrè fún ọgbọ́n àti ìmọ̀ láti ṣàkóso àwọn ènìyàn mi tí èmi fi ọ́ jẹ ọba lé lórí.
Olelo mai la ke Akua ia Solomona, No ka mea, aia no ma kou naau keia, aole oe i noi mai i ka waiwai a me ka hanohano, a me ka make ana o kou poe enemi, aole no hoi oe i noi mai i na la he nui loa; aka, ua noi mai oe nou i ka naauao, a me ke akamai, i hiki ia oe ke hoomalu i ko'u poe kanaka maluna o lakou i hoalii aku ai au ia oe;
12 Nítorí náà, ọgbọ́n àti ìmọ̀ ni a ó fi fún ọ, Èmi yóò sì fún ọ ní ọrọ̀, ọlá àti ọ̀wọ̀, irú èyí tí ọba ti ó wà ṣáájú rẹ kò ní, tí àwọn tí ń bọ̀ lẹ́yìn rẹ kò sì ní ní irú rẹ̀.”
Nolaila, ua haawiia ia oe ka naauao, a me ke akamai, a e haawi aku no hoi au ia oe i ka waiwai, a me ka hanohano: aole pela kekahi o na'lii mamua, aole no hoi he mea like mamuli aku.
13 Nígbà náà ni Solomoni sì ti ibi gíga Gibeoni lọ sí Jerusalẹmu láti iwájú àgọ́ ìpàdé. Ó sì jẹ ọba lórí Israẹli.
Hele mai la o Solomona mai kahi kiekio mai, ma Gibeona, a hiki i Ierusalema, maimua mai o ka halelewa o ke anainakanaka, a noho alii iho la ia maluna o ka Iseraela.
14 Solomoni kó kẹ̀kẹ́ àti ẹṣin jọ, ó sì ní ẹgbàáje kẹ̀kẹ́ àti ẹgbàá mẹ́fà ẹlẹ́ṣin, tí ó kó pamọ́ sí ìlú kẹ̀kẹ́ ogun àti pẹ̀lú rẹ̀ ni Jerusalẹmu.
A houluulu o Solomona i na kaa, a me na hooholo lio; aia no ia ia na kaa hookahi tausani, a me na haneri eha, a me na hooholo lio he umikumamalua tausani. A waiho oia ia mau mea ma na kulanakauhale no na kaa, a ma kahi o ke alii ma Ierusalema.
15 Ọba náà ṣe fàdákà àti wúrà gẹ́gẹ́ bí ó ti wọ́pọ̀ ní Jerusalẹmu bí òkúta, àti kedari ó pọ̀ bí igi sikamore ní àwọn ẹsẹ̀ òkè.
A hoolilo ae la ke alii i ke kala a me ke gula ma Ierusalema e like me na pohaku; i kona imi ana no hoi, nui iho la na laau kedera e like me na laau sukomorea ma ke awawa.
16 Àwọn ẹṣin Solomoni ní a gbà láti ìlú òkèrè Ejibiti àti láti kún ọ̀gbọ̀ oníṣòwò ti ọba ni gba okun náà ní iye kan.
A ua kaiia mai na lio no Solomona mai Aigupita mai, a na na huakai kalepa a ke alii i lawe ma ke kumukuai.
17 Wọ́n ra kẹ̀kẹ́ kan láti Ejibiti. Fún ẹgbẹ̀ta ṣékélì fàdákà àti ẹṣin kan fún ọgọ́rin méjìdínláàádọ́ta. Wọ́n ko wọn lọ sọ́dọ̀ àwọn ọba mìíràn ti Hiti àti ti àwọn ará Aramu.
A kii aku la lakou a kai mai, mai Aigupita mai, i ke kaa hookahi, no na haneri sekela kala eono, a i ka lio no ka haneri me kanalima. A pela no lakou i lawe mai ai no na'lii a pau o ka Heta, a me na'lii o Suria ma ko lakou lima.

< 2 Chronicles 1 >