< 1 Chronicles 2 >

1 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Israẹli. Reubeni, Simeoni, Lefi, Juda, Isakari, Sebuluni,
Oto są synowie Izraela: Ruben, Symeon, Lewi i Juda, Issachar i Zebulon;
2 Dani, Josẹfu, Benjamini; Naftali, Gadi: àti Aṣeri.
Dan, Józef, Beniamin, Neftali, Gad i Aszer.
3 Àwọn ọmọ Juda: Eri, Onani àti Ṣela, àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta wọ̀nyí ni wọ́n bí fún un láti ọ̀dọ̀ arábìnrin Kenaani, ọmọbìnrin Ṣua. Eri àkọ́bí Juda, ó sì burú ní ojú Olúwa, bẹ́ẹ̀ ni Olúwa sì pa á.
Synowie Judy: Er, Onan i Szela. Ci trzej urodzili mu się z córki Szui, Kananejki. Ale Er, pierworodny Judy, był zły w oczach PANA, dlatego go zabił.
4 Tamari, aya ọmọbìnrin Juda, ó sì bí Peresi àti Sera sì ní ọmọ márùn-ún ní àpapọ̀.
Tamar zaś, jego synowa, urodziła mu Peresa i Zeracha. Wszystkich synów Judy było pięciu.
5 Àwọn ọmọ Peresi: Hesroni àti Hamulu.
Synowie Peresa: Chesron i Chamul.
6 Àwọn ọmọ Sera: Simri, Etani, Hemani, Kalkoli àti Dara, gbogbo wọn jẹ́ márùn-ún.
Synowie Zeracha: Zimri, Etan, Heman, Kalkol i Dara, wszystkich ich [było] pięciu.
7 Àwọn ọmọ Karmi: Akani, ẹni tí ó mú ìyọnu wá sórí Israẹli nípa ẹ̀ṣẹ̀ ìfibú lórí mímú ohun ìyàsọ́tọ̀.
Synowie Karmiego: Achar, który sprowadził nieszczęście na Izraela, gdy zgrzeszył przy rzeczach przeklętych.
8 Àwọn ọmọ Etani: Asariah.
Synowie Etana: Azariasz.
9 Àwọn ọmọ tí a bí fún Hesroni ni: Jerahmeeli, Ramu àti Kalebu.
Synowie Chesrona, którzy mu się urodzili: Jerachmeel, Ram i Kelubaj.
10 Ramu sì ni baba Amminadabu, àti Amminadabu baba Nahiṣoni olórí àwọn ènìyàn Juda.
Ram zaś spłodził Amminadaba, a Amminadab spłodził Nachszona, księcia synów Judy.
11 Nahiṣoni sì ni baba Salmoni, Salmoni ni baba Boasi,
A Nachszon spłodził Salmę, a Salma spłodził Boaza.
12 Boasi baba Obedi àti Obedi baba Jese.
A Boaz spłodził Obeda, a Obed spłodził Jessego.
13 Jese sì ni baba Eliabu àkọ́bí rẹ̀; ọmọ ẹlẹ́ẹ̀kejì sì ni Abinadabu, ẹlẹ́ẹ̀kẹta ni Ṣimea,
A Jesse spłodził swego pierworodnego Eliaba, [jako] drugiego – Abinadaba, trzeciego – Szimeę;
14 ẹlẹ́ẹ̀kẹrin Netaneli, ẹlẹ́ẹ̀karùnún Raddai,
Czwartego – Netaneela, piątego – Raddaja;
15 ẹlẹ́ẹ̀kẹfà Osemu àti ẹlẹ́ẹ̀keje Dafidi.
Szóstego – Osema, siódmego – Dawida.
16 Àwọn arábìnrin wọn ni Seruiah àti Abigaili. Àwọn ọmọ mẹ́ta Seruiah ni Abiṣai, Joabu àti Asaheli.
A ich siostry to Seruja i Abigail. Synowie Serui: Abiszaj, Joab i Asahel – ci trzej.
17 Abigaili ni ìyá Amasa, ẹni tí baba rẹ̀ sì jẹ́ Jeteri ará Iṣmaeli.
Abigail zaś urodziła Amasę, ojcem Amasy [był] Jeter, Izmaelita.
18 Kalebu ọmọ Hesroni ní ọmọ láti ọ̀dọ̀ ìyàwó rẹ̀ Asuba (láti ọ̀dọ̀ Jerioti). Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ rẹ̀: Jeṣeri, Ṣobabu àti Ardoni.
Kaleb, syn Chesrona, spłodził [dzieci] z Azubą, [swoją] żoną, i z Jeriotą. A jej synami byli: Jeszer, Szobab i Ardon.
19 Nígbà tí Asuba sì kú, Kalebu sì fẹ́ Efrata ní aya, ẹni tí ó bí Huri fún un.
A gdy Azuba umarła, Kaleb pojął sobie za żonę Efratę, która urodziła mu Chura.
20 Huri ni baba Uri, Uri sì jẹ́ baba Besaleli.
A Chur spłodził Uriego, a Uri spłodził Besaleela.
21 Nígbà tí ó yá, Hesroni sì dùbúlẹ̀ pẹ̀lú ọmọbìnrin Makiri baba Gileadi (ó sì ti fẹ́ ní aya láti ìgbà tí ó ti wà ní ẹni ọgọ́ta ọdún) ó sì bí Segubu.
Potem Chesron obcował z córką Makira, ojca Gileada, i wziął ją za żonę, mając sześćdziesiąt lat, a ta urodziła mu Seguba.
22 Segubu sì jẹ́ baba Jairi, ẹni tí ó jẹ́ olùdarí ìlú mẹ́tàlélógún ní ilẹ̀ Gileadi.
A Segub spłodził Jaira, który miał dwadzieścia trzy miasta w ziemi Gilead.
23 (Ṣùgbọ́n Geṣuri àti Aramu sì fi agbára gba Hafoti-Jairi, àti Kenati pẹ̀lú gbogbo agbègbè rẹ̀ tí wọn tẹ̀dó sí jẹ́ ọgọ́ta ìlú.) Gbogbo wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Makiri baba Gileadi.
Zabrał bowiem Geszurze i Aramowi wsie Jaira oraz Kenat i przyległe do niego miasteczka: razem sześćdziesiąt miast. Wszystkie one [należały do] synów Makira, ojca Gileada.
24 Lẹ́yìn tí Hesroni sì kú ni Kalebu Efrata, Abijah ìyàwó rẹ̀ ti Hesroni sì bí Aṣihuri baba Tekoa fún un.
Po śmierci Chesrona w Kaleb-Efrata, żona Chesrona, Abija, urodziła mu Aszura, ojca Tekoa.
25 Ọmọ Jerahmeeli àkọ́bí Hesroni: Ramu ọmọ àkọ́bí rẹ̀ Buna, Oreni, Osemu àti Ahijah.
Synami Jerachmeela, pierworodnego Chesrona, byli: pierworodny Ram, następnie Buna, Oren, Ozem i Achiasz.
26 Jerahmeeli ní ìyàwó mìíràn, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Atara; ó sì jẹ́ ìyá fún Onamu.
Jerachmeel miał także drugą żonę imieniem Atara. [Była] ona matką Onama.
27 Àwọn ọmọ Ramu àkọ́bí Jerahmeeli: Maasi, Jamini àti Ekeri.
Synami Rama, pierworodnego Jerachmeela, [byli]: Maas, Jamin i Eker.
28 Àwọn ọmọ Onamu: Ṣammai àti Jada. Àwọn ọmọ Ṣammai: Nadabu àti Abiṣuri.
Synami Onama byli Szammaj i Jada. Synami Szammaja: Nadab i Abiszur.
29 Orúkọ ìyàwó Abiṣuri ni Abihaili ẹni tí ó bí Ahbani àti Molidi.
Żona Abiszura miała na imię Abihail i urodziła mu Achbana i Molida.
30 Àwọn ọmọ Nadabu Seledi àti Appaimu. Seledi sì kú láìsí ọmọ.
Synowie Nadaba: Seled i Appaim. Lecz Seled umarł bez potomstwa.
31 Àwọn ọmọ Appaimu: Iṣi, ẹni tí ó jẹ́ baba fún Ṣeṣani. Ṣeṣani sì jẹ́ baba fún Ahlai.
Synowie Appaima: Jiszi. Synowie Jisziego: Szeszan, a córka Szeszana: Achlaj.
32 Àwọn ọmọ Jada, arákùnrin Ṣammai: Jeteri àti Jonatani. Jeteri sì kú láìní ọmọ.
Synowie Jady, brata Szammaja: Jeter i Jonatan. A Jeter umarł bez potomstwa.
33 Àwọn ọmọ Jonatani: Peleti àti Sasa. Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Jerahmeeli.
Synowie Jonatana: Pelet i Zaza. Byli oni synami Jerachmeela.
34 Ṣeṣani kò sì ní ọmọkùnrin àwọn ọmọbìnrin nìkan ni ó ní. Ó sì ní ìránṣẹ́ ará Ejibiti tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Jariha.
Lecz Szeszan nie miał synów, tylko córki. Miał też Szeszan sługę Egipcjanina imieniem Jarcha.
35 Ṣeṣani sì fi ọmọ obìnrin rẹ̀ ní aya fún ìránṣẹ́ rẹ̀ Jariha, ó sì bí ọmọ fún tí orúkọ rẹ̀ jẹ́ Attai.
Dał więc Szeszan swemu słudze Jarsze swoją córkę za żonę, a ona urodziła mu Attaja.
36 Attai sì jẹ́ baba fún Natani, Natani sì jẹ́ baba fún Sabadi,
Attaj spłodził Natana, a Natan spłodził Zabada.
37 Sabadi ni baba Eflali, Eflali jẹ́ baba Obedi,
Zabad spłodził Eflala, a Eflal spłodził Obeda.
38 Obedi sì ni baba Jehu, Jehu ni baba Asariah,
Obed spłodził Jehu, a Jehu spłodził Azariasza.
39 Asariah sì ni baba Helesi, Helesi ni baba Eleasa,
Azariasz spłodził Chelesa, a Cheles spłodził Eleasę.
40 Eleasa ni baba Sismai, Sismai ni baba Ṣallumu,
Eleasa spłodził Sismaja, a Sismaj spłodził Szalluma.
41 Ṣallumu sì ni baba Jekamiah, Jekamiah sì ni baba Eliṣama.
A Szallum spłodził Jekamiasza, a Jekamiasz spłodził Eliszamę.
42 Àwọn ọmọ Kalebu arákùnrin Jerahmeeli: Meṣa àkọ́bí rẹ̀, ẹni tí ó jẹ́ baba fún Sifi, àti àwọn ọmọ rẹ̀ Meraṣa, ẹni tí ó jẹ́ baba fún Hebroni.
Synami Kaleba, brata Jerachmeela, [byli]: jego pierworodny Mesza, który był ojcem Zifa, i synowie Mareszy – ojcem Chebrona.
43 Àwọn ọmọ Hebroni: Kora, Tapua, Rekemu, àti Ṣema.
Synowie Chebrona: Korach, Tappuach, Rekem i Szema.
44 Ṣema ni baba Rahamu, Rahamu sì jẹ́ baba fún Jorkeamu. Rekemu sì ni baba Ṣammai.
Szema spłodził Rachama, syna Jorkoama, a Rekem spłodził Szammaja.
45 Àwọn ọmọ Ṣammai ni Maoni, Maoni sì ni baba Beti-Suri.
Synem Szammaja [był] Maon, a Maon [był] ojcem Bet-Sura.
46 Efani obìnrin Kalebu sì ni ìyá Harani, Mosa àti Gasesi, Harani sì ni baba Gasesi.
Efa, nałożnica Kaleba, urodziła Charana, Mosę i Gazeza, a Charan spłodził Gazeza.
47 Àwọn ọmọ Jahdai: Regemu, Jotamu, Geṣani, Peleti, Efani àti Ṣaafu.
Synowie Jahdaja: Regem, Jotam, Geszan, Pelet, Efa i Szaaf.
48 Maaka obìnrin Kalebu sì ni ìyá Seberi àti Tirhana.
Maaka, [druga] nałożnica Kaleba, urodziła Szebera i Tyrchanę.
49 Ó sì bí Ṣaafu baba Madmana, Ṣefa baba Makbena àti baba Gibeah, ọmọbìnrin Kalebu sì ni Aksa.
Urodziła również Szaafa, ojca Madmanny, i Szewę, ojca Makbeny i Gibea. A córką Kaleba [była] Aksa.
50 Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Kalebu. Àwọn ọmọ Huri, àkọ́bí Efrata: Ṣobali baba Kiriati-Jearimu.
Ci byli synami Kaleba, syna Chura, pierworodnego Efraty: Szobal, ojciec Kiriat-Jearima;
51 Salma baba Bẹtilẹhẹmu àti Harefu baba Beti-Gaderi.
Salma, ojciec Betlejema, i Charef, ojciec Bet-Gadera.
52 Àwọn ọmọ Ṣobali baba Kiriati-Jearimu ni: Haroe, ìdajì àwọn ará Manaheti.
Szobal, ojciec Kiriat-Jearima, miał synów: Haroego i połowę Manachytów.
53 Àti ìdílé Kiriati-Jearimu: àti àwọn ara Itri, àti àwọn ará Puti, àti àwọn ará Ṣumati àti àwọn ará Miṣraiti: láti ọ̀dọ̀ wọn ni àwọn ọmọ ará Sorati àti àwọn ará Eṣtaoli ti wá.
A rodziny Kiriat-Jearima [to]: Jitryci, Putyci, Szumatyci i Mirzaici, od których wywodzą się Soreatyci i Esztaolici.
54 Àwọn ọmọ Salma: Bẹtilẹhẹmu, àti àwọn ará Netofa, Atrotu Beti-Joabu, ìdajì àwọn ará Manahati, àti ará Sori,
Synowie Salmy: Betlejem, Netofatyci, Atrot, rodzina Joaba i połowa Manachytów, Soreici;
55 àti àwọn ìdílé àwọn akọ̀wé, ẹni tí ń gbé ní Jabesi: àti àwọn ọmọ Tirati àti àwọn ará Ṣimeati àti àwọn ará Sukati. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ará Keni, ẹni tí ó wá láti ọ̀dọ̀ Hamati, baba ilé Rekabu.
Rodziny pisarzy mieszkających w Jabes: Tyratyci, Szimeatyci i Sukatyci. Ci są Kenitami, którzy wywodzili się od Chamata, ojca domu Rechaba.

< 1 Chronicles 2 >