< Yeremia 49 >

1 Nea ɛfa Amonfo ho: Sɛɛ na Awurade se: “Israel nni mmabarima ana? Onni wɔn a wobedi nʼade? Ɛno de adɛn nti na Molek afa Gad ayɛ ne de yi? Adɛn nti na ne nkurɔfo tete ne nkurow mu?
Nípa Ammoni. Báyìí ni Olúwa wí, “Israẹli kò ha ní ọmọkùnrin? Israẹli kò ha ní àrólé bí? Nítorí kí ni Malkomu ṣe jogún Gadi? Kí ló dé tí àwọn ènìyàn rẹ̀ ń gbé ìlú rẹ̀?
2 Nanso nna no reba,” Awurade na ose. “Bere a mɛbobɔ mu de afrɛ ɔko atia Raba a ɛyɛ Amonfo de; ɛbɛyɛ afabo siw, wɔbɛto nkuraa a atwa ne ho ahyia no mu gya. Na Israel bɛpam wɔn a wɔpam no no,” sɛɛ na Awurade se.
Ṣùgbọ́n ọjọ́ náà ń bọ̀,” ni Olúwa wí; “nígbà tí èmi yóò mú kí a gbọ́ ìdágìrì ogun ní Rabba tí Ammoni; yóò sì di òkìtì ahoro, gbogbo ìlú tí ó yí i ká ni a ó jó níná. Nígbà náà ni Israẹli yóò lé wọn, àwọn tí ó ti lé e jáde,” ni Olúwa wí.
3 “Twa adwo. Hesbon, efisɛ wɔasɛe Ai! Monteɛ mu, mo a mowɔ Raba! Mumfura ayitam na munni awerɛhow; mommɔ nnyenyen wɔ afasu no mu, efisɛ Molek bɛkɔ nnommum mu, ɔne nʼasɔfo ne nʼadwumayɛfo.
“Hu, ìwọ Heṣboni, nítorí Ai tí rún! Kígbe ẹ̀yin olùgbé Rabba! Ẹ wọ aṣọ ọ̀fọ̀ kí ẹ sì ṣọ̀fọ̀. Ẹ sáré sókè sódò nínú ọgbà, nítorí Malkomu yóò lọ sí ìgbèkùn, pẹ̀lú àwọn àlùfáà àti ìjòyè rẹ̀.
4 Adɛn nti na wode wʼabon ahorow no hoahoa wo ho, wʼabon a wunya mu aba bebree no nti? Amon Babea a Onni nokware, wode wo ho to wʼahonya so na woka se, ‘Hena na ɔbɛtow ahyɛ me so?’
Èéṣe tí ìwọ fi ń ṣògo nínú àfonífojì rẹ, ṣògo nínú àfonífojì rẹ fún èso? Ẹ̀yin ọmọbìnrin Ammoni aláìṣòótọ́, ẹ gbẹ́kẹ̀lé ọrọ̀ yín, ẹ sì wí pé, ‘Ta ni yóò kò mí lójú?’
5 Mede ehu bɛba wo so, ebefi wɔn a wɔatwa wo ho ahyia no nyinaa,” Awurade na ose, Asafo Awurade no. “Wɔbɛpam mo nyinaa, na obiara remmoaboa akobɔfo ano.
Èmi yóò mu ẹ̀rù wá lórí rẹ láti ọ̀dọ̀ gbogbo àwọn tó yí ọ ká,” ni Olúwa, ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
6 “Nanso akyiri no, mɛsan de Amonfo adenya ama wɔn,” sɛe na Awurade se.
“Olúwa àwọn ọmọ-ogun. Gbogbo yín ni ó lé jáde, kò sì ṣí ẹnìkan tí yóò dá ìkólọ Ammoni padà,” ni Olúwa wí.
7 Nea ɛfa Edom ho: Sɛɛ na Asafo Awurade se: “Nyansa nni Teman bio ana? Afotu ayera wɔ anyansafo mu ana? Wɔn nyansa no aporɔw ana?
Nípa Edomu. Èyí ní ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Ṣe kò ha sí ọgbọ́n mọ́ ni Temani? Ṣé a ti ké ìmọ̀ràn kúrò ní ọ̀dọ̀ olóyè? Ṣé ọgbọ́n wọn ti bàjẹ́ bí?
8 Monnan mo ho na munguan, monkɔtetɛw abodan a mu dɔ mu, mo a motete Dedan, efisɛ mede amanehunu bɛba Esau so wɔ bere a mɛtwe nʼaso no.
Yípadà kí o sálọ, sá pamọ́ sínú ihò, ìwọ tí ó ń gbé ní Dedani, nítorí èmi yóò mú ibi wá sórí Esau, ní àkókò tí èmi ó bẹ̀ ẹ́ wò.
9 Sɛ bobetetewfo no baa mo nkyɛn a anka wɔrennya bobe no kakra ana? Sɛ akorɔmfo baa ɔdasu mu a, anka wɔrenwia ade dodow a wɔpɛ ana?
Tí àwọn tí ń ṣa èso bá tọ̀ ọ́ wá; ǹjẹ́ wọn kò ní fi èso díẹ̀ sílẹ̀? Tí olè bá wá ní òru; ǹjẹ́ wọn kò ní kó gbogbo ohun tí wọ́n bá fẹ́?
10 Na mɛma Esau ada adagyaw. Mɛda ne hintabea ahorow adi, sɛnea ɔrentumi mfa ne ho nhintaw. Ne mma, nʼabusuafo ne ne mfɛfo bewuwu, na wɔrenhu no bio.
Ṣùgbọ́n èmi yóò tu Esau sí ìhòhò, èmi ti fi ibi ìkọ̀kọ̀ rẹ̀ hàn, nítorí kí o máa ba à fi ara rẹ pamọ́. Àwọn ọmọ rẹ, ẹbí rẹ àti àwọn ará ilé rẹ yóò parun. Wọn kò sì ní sí mọ́.
11 Munnyaw mo ayisaa, mɛbɔ wɔn nkwa ho ban. Mo akunafo nso betumi de wɔn ho ato me so.”
Fi àwọn ọmọ aláìní baba sílẹ̀ èmi yóò dáàbò bo ẹ̀mí wọn. Àwọn opó rẹ gan an lè gbẹ́kẹ̀lé mi.”
12 Nea Awurade se ni: “Sɛ ɛsɛ sɛ wɔn a wɔmfata sɛ wɔnom kuruwa no nom a, ɛno de adɛn nti na ɛnsɛ sɛ wɔtwe mo aso? Wɔbɛtwe mo aso na mobɛnom nso.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí bí ẹnikẹ́ni tí kò bá yẹ kí ó mu ago náà bá mú un, kí ló dé tí ìwọ yóò fi lọ láìjìyà? Ìwọ kò ní lọ láìjìyà; ṣùgbọ́n ìwọ yóò mú un.
13 Meka me ho ntam sɛ wɔbɛsɛe Bosra na ayɛ ahodwiriwde, ahohorade ne nnome; na ne nkurow nyinaa bɛsɛe afebɔɔ,” Awurade na ose.
Èmi fi ara mi búra ni Olúwa wí, wí pé, “Bosra yóò ba ayé ara rẹ̀ jẹ́. Yóò di ẹni ẹ̀gàn, ẹni èpè àti ẹni ègún, àti gbogbo ìlú rẹ̀ yóò di ìbàjẹ́ títí láé.”
14 Mate asɛm a efi Awurade nkyɛn: wɔsomaa ananmusini bi sɛ ɔnkɔka nkyerɛ amanaman no se, “Mommoaboa mo ho ano nkɔtow nhyɛ no so! Monsɔre nkɔ ɔko!”
Ní gbígbọ́, èmi ti gbọ́ ìró kan láti ọ̀dọ̀ Olúwa, a rán ikọ̀ kan sí orílẹ̀-èdè pé, ẹ kó ara yín jọ, ẹ wá sórí rẹ̀, ẹ sì dìde láti jagun.
15 “Na mɛyɛ wo ketewa wɔ aman no mu, na wɔabu wo animtiaa.
“Ní báyìí, èmi yóò sọ ọ́ di kékeré láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo; ẹni ẹ̀gàn láàrín àwọn ènìyàn.
16 Ehu a wobɔ ne koma mu ahomaso adaadaa wo, wo a wote abotan ntokuru mu, na wote koko no sorɔnsorɔmmea. Ɛwɔ mu, woyɛ wo berebuw wɔ sorosoro sɛ ɔkɔre de, nanso hɔ na mefi de wo aba fam,” Awurade na ose.
Ìpayà tí ìwọ ti fà sínú ìgbéraga ọkàn rẹ sì ti tàn ọ́ jẹ; ìwọ tí ń gbé ní pàlàpálá àpáta, tí o jókòó lórí ìtẹ́ gíga síbẹ̀ o kọ́ ìtẹ́ rẹ ga gẹ́gẹ́ bí ẹyẹ idì; láti ibẹ̀ ni èmi yóò ti mú ọ sọ̀kalẹ̀ wá,” ni Olúwa wí.
17 “Edom bɛyɛ ahodwiriwde; wɔn a wotwa mu wɔ hɔ no nyinaa ho bedwiriw wɔn na wɔadi ne ho fɛw esiane nʼapirakuru nyinaa nti.
“Edomu yóò di ahoro gbogbo àwọn tí ń kọjá yóò jáyà, wọn ó sì fi rẹ́rìn-ín ẹlẹ́yà nítorí gbogbo ìpalára rẹ.
18 Sɛnea wɔdan Sodom ne Gomora ne wɔn nkurow gui no,” Awurade na ose, “saa ara na obiara rentena hɔ; onipa biara rentena mu.
Gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe gba Sodomu àti Gomorra pẹ̀lú àwọn ìlú tí ó wà ní àyíká rẹ,” ní Olúwa wí. “Bẹ́ẹ̀ ni, kò sí ẹnikẹ́ni tí yóò gbé níbẹ̀; kò sì ní sí ènìyàn tí yóò tẹ̀dó síbẹ̀ mọ́.
19 “Sɛnea gyata a ofi Yordan nkyɛkyerɛ mu rekɔ adidibea frɔmfrɔm no, saa ara na mɛtaa Edom afi nʼasase so wɔ bere tiaa bi mu. Hena ne nea mayi no sɛ ɔnyɛ eyi? Hena na ɔte sɛ me, na hena na obetumi ne me adi asi? Na oguanhwɛfo bɛn na obetumi asɔre atia me?”
“Bí i kìnnìún ni òun ó gòkè wá láti igbó Jordani sí orí ilẹ̀ ọlọ́ràá, Èmi ó lé Edomu kúrò ní ilẹ̀ rẹ̀ ní kíákíá. Ta ni àyànfẹ́ náà tí èmi ó yàn sórí rẹ̀? Ta ló dàbí mi, ta ni ó sì pé mi ṣe ẹlẹ́rìí? Ta ni olùṣọ́-àgùntàn náà tí yóò le dúró níwájú mi?”
20 Enti tie nea Awurade ahyehyɛ atia Edom, nea wabɔ ne tirim sɛ ɔbɛyɛ de atia wɔn a wɔte Teman ni: Nguankuw no mu nkumaa no wɔbɛtwe wɔn akɔ; wɔn nti ɔbɛsɛe adidibea no koraa.
Nítorí náà, ẹ gbọ́ ohun tí Olúwa ní fún Edomu, ohun tí ó ní ní pàtàkì fún àwọn tí ń gbé ní Temani. Àwọn ọ̀dọ́ àgbò ni à ó lé jáde; pápá oko wọn ni yóò run nítorí wọn.
21 Wɔn asehwe nnyigyei bɛma asase awosow; wɔn nteɛteɛmu gyegyeegye akodu Po Kɔkɔɔ ho.
Ilẹ̀ yóò mì tìtì nípa ariwo ìṣubú wọn, a ó gbọ́ igbe wọn ní Òkun pupa.
22 Monhwɛ! Ɔkɔre bi betu akɔ soro na wabɔ hoo aba fam a watrɛtrɛw ne ntaban mu wɔ Bosra so. Saa da no Edom dɔmmarima koma betu sɛ ɔbea a ɔrekyem wɔ awo so.
Wò ó! Ẹyẹ idì yóò gòkè fò wálẹ̀, yóò tẹ ìyẹ́ rẹ̀ lórí Bosra. Ní ọjọ́ náà ọkàn àwọn ajagun Edomu yóò dàbí ọkàn obìnrin tí ń rọbí.
23 Nea ɛfa Damasko ho: “Hamat ne Arpad di yaw, efisɛ wɔate asɛmmɔne. Wɔn koma abotow te sɛ po a ayɛ hagyahagya.
Nípa Damasku. “Inú Hamati àti Arpadi bàjẹ́ nítorí wọ́n gbọ́ ìròyìn búburú, ìjayà dé bá wọn, wọ́n sì dààmú bí omi Òkun.
24 Damasko ayɛ mmerɛw, wayɛ sɛ ɔrebeguan wabɔ huboa; ahoyeraw ne ɔyaw akyekyere no, ɔyaw a ɛte sɛ ɔbea a, ɔrekyem wɔ awo so.
Damasku di aláìlera, ó pẹ̀yìndà láti sálọ, ìwárìrì sì dé bá a; ìbẹ̀rù àti ìrora dìímú, ìrora bí ti obìnrin tí ó wà ní ipò ìrọbí.
25 Adɛn nti na wonnyaw kuropɔn a agye din yi ntoo hɔ, kurow a mʼani gye mu?
Kí ló dé tí ìlú olókìkí di ohun ìkọ̀sílẹ̀; ìlú tí mo dunnú sí.
26 Ampa ara ne mmerante bɛtotɔ wɔ mmɔnten so; wɔbɛma nʼasraafo nyinaa aka wɔn ano ato mu saa da no,” sɛɛ na Asafo Awurade se.
Lóòtítọ́, àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin rẹ yóò ṣubú lójú pópó, gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ yóò pa ẹnu mọ́ ní ọjọ́ náà,” ní Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
27 “Mede ogya bɛto Damasko afasu mu; na ɛbɛhyew Ben-Hadad aban.”
“Èmi yóò fi iná sí odi Damasku, yóò sì jó gbọ̀ngàn Beni-Hadadi run.”
28 Nea ɛfa Kedar ne Hasor ahenni, a Babiloniahene Nebukadnessar tow hyɛɛ so no. Sɛɛ na Awurade se: “Sɔre na kɔtow hyɛ Kedar so na sɛe nnipa a wɔwɔ apuei fam no.
Nípa ìlú Kedari àti ìjọba Hasori èyí ti Nebukadnessari ọba Babeli dojú ìjà kọ, èyí ni ohun tí Olúwa sọ, “Dìde kí o sì dojú ìjà kọ ìlú Kedari, kí o sì pa àwọn ènìyàn ìlà-oòrùn run.
29 Wɔbɛfa wɔn ntamadan ne wɔn nguankuw; wɔbɛfa wɔn nkataso, ne wɔn ho nneɛma ne yoma akɔ. Nnipa bɛteɛteɛ mu se, ‘Ehu wɔ baabiara!’
Àgọ́ wọn àti agbo àgùntàn wọn ni wọn ó kó lọ; àgọ́ wọn yóò di ìṣínípò padà pẹ̀lú gbogbo ẹrù àti ìbákasẹ wọn. Àwọn ènìyàn yóò ké sórí wọ́n pé, ‘Ẹ̀rù yí káàkiri!’
30 “Munguan nkɔ ntɛmntɛm! Monhyehyɛ abodan a mu dɔ mu, mo a motete Hasor,” Awurade na ose. “Babiloniahene Nebukadnessar apam mo ti so; wayɛ nhyehyɛe a etia mo.
“Sálọ kíákíá! Fi ara pamọ́ sí ibi jíjìn, ẹ̀yin olùgbé Hasori,” ni Olúwa wí. “Nebukadnessari ọba Babeli ti dojú ìjà kọ ọ́.
31 “Sɔre kɔtow hyɛ ɔman bi so a woremmrɛ, ɔman a wɔte ahotoso mu,” Awurade na ose, “ɔman a wonni apon anaa akwanside; na emu nnipa nko ara na wɔte.
“Dìde kí o sì dojú ìjà kọ orílẹ̀-èdè tí ó wà nínú ìrọ̀rùn, èyí tí ó gbé ní àìléwu,” ní Olúwa wí. “Orílẹ̀-èdè tí kò ní odi tàbí irin, àwọn ènìyàn rẹ̀ ń dágbé.
32 Wɔn mfurum bɛyɛ asade, na wɔn anantwikuw akɛse no bɛyɛ asade. Mɛbɔ saa nnipa a wɔtete akyirikyiri no ahwete ama mframa no, na mede amanehunu befi afa nyinaa aba wɔn so,” Awurade na ose.
Àwọn ìbákasẹ á di ẹrù àti àwọn ẹran ọ̀sìn, wọ́n á di ìkógun. Èmi yóò tú àwọn tí ó wà ní òkèèrè sí inú afẹ́fẹ́. Èmi yóò sì mú ibi wá sí àyíká gbogbo,” báyìí ní Olúwa wí.
33 “Hasor bɛyɛ ahade ama adompo, ɛbɛda mpan afebɔɔ. Obiara rentena hɔ; onipa biara rentena mu.”
“Hasori yóò di ibi ìdọdẹ àwọn akátá, ibi ìkọ̀sílẹ̀ ayérayé, kò sí ẹni tí yóò gbé ní ibẹ̀.”
34 Eyi ne asɛm a, efi Awurade nkyɛn baa odiyifo Yeremia hɔ a ɛfa Elam ho, wɔ Yudahene Sedekia adedi mfiase:
Èyí ní ọ̀rọ̀ Olúwa èyí tí ó tọ Jeremiah wòlíì wá nípa Elamu ní ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Sedekiah ọba Juda.
35 Sɛɛ na Asafo Awurade se: “Hwɛ mebubu Elam agyan mu, nea wɔn ahoɔden gyina so no.
Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ: “Wò ó, èmi yóò fọ́ ìtẹ̀gùn Elamu, ẹni tí wọ́n sinmi lé nípa agbára.
36 Mede mframa anan no bɛba Elam so afi ɔsorosoro afanan; mɛbɔ wɔn ahwete mframa anan no mu, na ɔman biara nni hɔ a Elam atubrafo renkɔ so.
Èmi yóò mú kí afẹ́fẹ́ orígun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin àgbáyé lòdì sí Elamu. Èmi yóò tú wọn ká sí ìpín afẹ́fẹ́ mẹ́rin àti pé, kò sí orílẹ̀-èdè tí ilẹ̀ àjèjì Elamu kò ní lọ.
37 Mɛbɔ Elam ahwete wɔ wɔn atamfo anim, wɔ wɔn a wɔrehwehwɛ wɔn akum wɔn no anim; mede amanehunu bɛba wɔn so mpo mʼabufuwhyew no,” Awurade na ose. “Mede afoa bɛtaa wɔn kosi sɛ, mewie wɔn korakora.
Èmi yóò kẹ́gàn Elamu níwájú àwọn ọ̀tá wọn, àti níwájú àwọn tí wọ́n ń wá ẹ̀mí wọn, Èmi yóò mú ibi wá sí orí wọn, àní, ìbínú gbígbóná mi,” bẹ́ẹ̀ ni Olúwa wí. “Èmi yóò lé wọn pẹ̀lú idà, di ìgbà tí èmi yóò rẹ́yìn wọn.
38 Mesi mʼahengua wɔ Elam na masɛe ne hene ne nʼadwumayɛfo,” Awurade na ose.
Èmi yóò sì gbé ìtẹ́ mi kalẹ̀ ní Elamu, èmí yóò sì pa ọba wọn àti ìjòyè wọn run,” báyìí ni Olúwa wí.
39 “Nanso mɛsan de Elam adenya ama no nna a ɛreba no mu,” Awurade na ose.
“Síbẹ̀, èmi yóò dá ìkólọ Elamu padà láìpẹ́ ọjọ́,” báyìí ni Olúwa wí.

< Yeremia 49 >