< Книга Иисуса Навина 19 >

1 И изыде вторый жребий Симеону, племени сынов Симеоновых по сонмом их, и бысть наследие их посреде жребия сынов Иудиных.
Kèké kejì jáde fún ẹ̀yà Simeoni, ní agbo ilé, ní agbo ilé. Ìní wọn sì wà ní àárín ilẹ̀ Juda.
2 И бысть жребий их Вирсавее и Савее и Молада,
Lára ìpín wọn ní: Beerṣeba (tàbí Ṣeba), Molada,
3 и Асерсуал и Вафул, и Велвола и Асом,
Hasari-Ṣuali, Bala, Esemu,
4 и Елфулад и Ерма,
Eltoladi, Betuli, Horma,
5 и Секелаг и Вефаммаргасвоф, и Асерсусим
Siklagi, Beti-Markaboti, Hasari Susa,
6 и Вефалваф, и села их: грады тринадесять и веси их.
Beti-Lebaoti àti Ṣarueli, ìlú wọn jẹ́ mẹ́tàlá àti ìletò wọn.
7 Аин и Реммоф, и Еефер и Асам, грады четыри и веси их:
Aini, Rimoni, Eteri àti Aṣani, ìlú wọn jẹ́ mẹ́rin àti ìletò wọn,
8 и вся предградия, яже окрест градов сих даже до Ваалферирраммоф, идущих во Иамеф к ливу. Сие наследие племен сынов Симеоновых по сонмом их.
àti gbogbo àwọn agbègbè ìlú wọ̀nyí títí dé Baalati-Beeri (Rama ní gúúsù). Èyí ni ilẹ̀ ìní ẹ̀yà àwọn ọmọ Simeoni, agbo ilé, ní agbo ilé.
9 От жребия Иудина наследие племене сынов Симеоновых, яко бысть часть сынов Иудиных болшая нежели их: и наследиша сынове Симеоновы посреде жребия их.
A mú ogún ìní àwọn ọmọ Simeoni láti ìpín Juda, nítorí ìpín Juda pọ̀ ju èyí tí wọ́n nílò lọ. Báyìí ni àwọn ọmọ Simeoni gba ìní wọn ní àárín ilẹ̀ Juda.
10 И изыде жребий третий Завулону по сонмом их: и будут пределы наследия их до Сарида:
Kèké kẹta jáde fún Sebuluni, ní agbo ilé ní agbo ilé ààlà ìní wọn sì lọ títí dé Saridi.
11 и восходят пределы их к морю и Мариле, и дойдут к Давасефу, и снидутся в дебрь, яже есть к лицу Иекнама,
Ó sì lọ sí ìwọ̀-oòrùn ní Marala, ó sì dé Dabbeṣeti, ó sì lọ títí dé odo ní ẹ̀bá Jokneamu.
12 и обратятся от Сарида противу от востоков Самес на пределы Хасалоф-Фавор, и пройдут к Даврафу, и взыдут к Иафаги:
Ó sì yípadà sí ìlà-oòrùn láti Saridi sí ìhà ìlà-oòrùn dé ilẹ̀ Kisiloti-Tabori, ó sì lọ sí Daberati, ó sì gòkè lọ sí Jafia.
13 и оттуду обыдут супротив на востоки в Гефаефер, во град Касим, и пройдут на Реммонам Мафарим Аннуа,
Nígbà náà ní o lọ sí ìhà ìlà-oòrùn lọ sí Gati-Heferi àti Eti-Kaṣini, ó sì jáde ní Rimoni, ó sì yí sí ìhà Nea.
14 и обыдут пределы к северу на Еннафоф, и будет исход их к Гаю Иеффаил,
Ní ibẹ̀, ààlà sì yíká ní ìhà àríwá lọ sí Hnatoni ó sì pín ní àfonífojì Ifita-Eli.
15 и Каттаф и Наалол, и Семрон и Иадила и Вифлеем: грады дванадесять и веси их.
Lára wọn ni Katati, Nahalali, Ṣimroni, Idala àti Bẹtilẹhẹmu. Wọ́n sì jẹ́ ìlú méjìlá àti ìletò wọn.
16 Сие наследие племене сынов Завулоновых по сонмом их, грады их и веси их.
Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní Sebuluni, ní agbo ilé agbo ilé.
17 И Иссахару изыде жребий четвертый, сыном Иссахаровым по сродством их,
Kèké kẹrin jáde fún Isakari, agbo ilé ní agbo ilé.
18 и быша пределы их Иезраель и Ахаселоф и Сунам,
Lára ilẹ̀ wọn ni èyí: Jesreeli, Kesuloti, Ṣunemu,
19 и Аферарим и Сиан, (и Ренаф) и Анахареф,
Hafraimu, Ṣihoni, Anaharati,
20 и Раввоф и Кесион и Аеме,
Rabiti, Kiṣioni, Ebesi,
21 и Рамаф и Инганним, и Инадда и Веффасис:
Remeti, Eni-Gannimu, Eni-Hada àti Beti-Pasesi.
22 и снидутся пределы к Фавору и к Сасимафу к морю, и вефсмас, и будет его исход предел Иордан: грады шестьнадесять и веси их.
Ààlà náà sì dé Tabori, Ṣahasuma, àti Beti-Ṣemeṣi, ó sì pin ní Jordani. Wọ́n sì jẹ́ ìlú mẹ́rìndínlógún àti ìletò wọn.
23 Сие наследие племене сынов Иссахаровых по сонмом их, грады и предградия их.
Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní ẹ̀yà Isakari, ní agbo ilé agbo ilé.
24 И изыде жребий пятый племене сынов Асировых по сонмом их,
Kèké karùn-ún jáde fún ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
25 и быша пределы их Хелкаф и Ооли, и Ватне и Ахсаф,
Lára ilẹ̀ wọn ni èyí: Helikati, Hali, Beteni, Akṣafu,
26 и Елимелех и Амад и Масал: и приближатся к Кармилу к морю, и Сиору и Лаванафу,
Allameleki, Amadi, àti Miṣali. Ní ìhà ìwọ̀-oòrùn ààlà náà dé Karmeli àti Ṣihori-Libinati.
27 и обратятся от восток солнца в Виф-Дагон, и приближатся к Завулону, и в Гай Иеффаил к северу, (и внидут пределы Асафа) в Виф-Аемек, и да идут по долине Аниила, и пройдут в Хавол ошуюю,
Nígbà náà ni o yí sí ìhà ìlà-oòrùn Beti-Dagoni, dé Sebuluni àti àfonífojì Ifita-Eli, ó sì lọ sí àríwá sí Beti-Emeki àti Neieli, ó sì kọjá lọ sí Kabulu ní apá òsì.
28 и Ахран и Роов, и Аммон и Кана, даже до Сидона великаго:
Ó sì lọ sí Abdoni, Rehobu, Hammoni àti Kana títí dé Sidoni ńlá.
29 и возвратятся пределы в Раму, и даже до града тверда Тириан, и возвратятся пределы до Сусы, и будет исход его море, и от ужа в Ахзиф,
Ààlà náà sì tẹ̀ sí ìhà Rama, ó sì lọ sí ìlú olódi Tire, ó sì yà sí Hosa, ó sì jáde ní Òkun Ńlá ní ilẹ̀ Aksibu,
30 и Амма и Афек и Раов: грады двадесять два и веси их.
Uma, Afeki àti Rehobu. Wọ́n sì jẹ́ ìlú méjìlélógún àti ìletò wọn.
31 Сие наследие племене сынов Асировых по сонмом их, грады их и веси их.
Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
32 И Неффалиму изыде жребий шестый, сыном Неффалимлим по сонмом их,
Ìpín kẹfà jáde fún Naftali, agbo ilé ní agbo ilé,
33 и быша пределы их Меелеф и Милон, и Весенаним и Арме, и Накев и Иавнил, даже до Лаккун: и быша исходи их Иордан:
ààlà wọn lọ láti Helefi àti igi ńlá ní Saananimu nímù; kọjá lọ sí Adami Nekebu àti Jabneeli dé Lakkumu, ó sì pín ní Jordani.
34 и возвратятся пределы к морю в Азаноф-Фавор, и пройдут оттуду во Икок, и приткнутся к Завулону от юга, и Асиру приближатся к морю, и ко Иуде Иордан от восток солнца.
Ààlà náà gba ìhà ìwọ̀-oòrùn lọ sí Asnoti-Tabori ó sì jáde ní Hukoki. Ó sì dé Sebuluni, ní ìhà gúúsù Aṣeri ní ìhà ìwọ̀-oòrùn àti Juda ní Jordani ní ìhà ìlà-oòrùn.
35 И грады ограждени Тириан, Тир и Амаф, и Реккаф и Хенероф,
Àwọn ìlú olódi sì Siddimu, Seri, Hamati, Rakàti, Kinnereti,
36 и Адами и Рама и Асор,
Adama, Rama Hasori,
37 и Кедес и Едраи и источник Асор,
Kedeṣi, Edrei, Eni-Aṣọri,
38 и Иарион и Магдалиил, Оран и Вефанаф и Фасмус: грады девятьнадесят и веси их.
Ironi, Migdali-Eli, Horemu, Beti-Anati àti Beti-Ṣemeṣi. Wọ́n sì jẹ́ ìlú mọ́kàndínlógún àti ìletò wọn.
39 Сие наследие племене сынов Неффалимлих по сродству их, грады и предградия их.
Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Naftali, ní agbo ilé sí agbo ilé.
40 И Дану и племени сынов Дановых по сонмом их изыде жребий седмый,
Ìbò kéje jáde fún ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé ní agbo ilé.
41 и быша пределы их Сараа и Есфаол и грады Самес,
Ilẹ̀ ìní wọn nìwọ̀nyí: Sora, Eṣtaoli, Iri-Ṣemesi,
42 и Саламинь и Еалон и Иефла,
Ṣaalabini, Aijaloni, Itila,
43 и Елон и Фамна и Аккарон,
Eloni, Timna, Ekroni,
44 и Елфеко и Гавафон и Ваафоф,
Elteke, Gibetoni, Baalati,
45 и Иуф и Ваниварак и Гефреммон,
Jehudu, Bene-Beraki, Gati-Rimoni,
46 и от моря Иераконска, и Ираккон, предел близ Иоппы, и изыде предел сынов Дановых от них.
Me Jakoni àti Rakkoni, pẹ̀lú ilẹ̀ tí ó kọjú sí Joppa.
47 И изыдоша сынове Дановы и воеваша Ласем, и взяша его и поразиша его острием меча: и обиташа в нем, и нарекоша имя его Ласендан, по имени Дана отца своего. И Аморрей остася жити во Еломе и в Саламине: и отяготе рука Ефремля на них, и быша им данницы.
(Ṣùgbọ́n àwọn ará Dani ní ìṣòro láti gba ilẹ̀ ìní wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n gòkè lọ, wọ́n sì kọlu Leṣemu, wọ́n sì gbà á, wọ́n sì fi idà kọlù ú, wọ́n sì ń gbé ibẹ̀. Wọ́n sì ń gbé ní Leṣemu, wọ́n sì pe orúkọ rẹ̀ ní Dani orúkọ baba ńlá wọn).
48 Сие наследие племене сынов Дановых по сонмом их, грады их и веси их. И не истребиша сынове Дановы Аморреа озлобляющаго их на горе, и не даяху им Аморрее исходити на юдоль, и утесниша от них предел части их.
Àwọn ìlú wọ́n yí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé agbo ilé.
49 И совершиша разделяти землю в пределех ея: и даша сынове Израилевы жребий Иисусу сыну Навину повелением Господним среде себе,
Nígbà tí wọ́n ti parí pínpín ilẹ̀ náà ní ìpín ti olúkúlùkù, àwọn ará Israẹli fún Joṣua ọmọ Nuni ní ìní ní àárín wọn,
50 и даша ему град, егоже проси, Фамнаф-Сараи, иже есть в горе Ефраим: и созда град, и вселися в нем.
bí Olúwa ti pàṣẹ, wọ́n fún un ni ìlú tí ó béèrè fún, Timnati Serah ní ìlú òkè Efraimu. Ó sì kọ́ ìlú náà, ó sì ń gbé ibẹ̀.
51 Сия разделения, яже разделиша Елеазар жрец и Иисус Навин и князи отечеств в племенех Израилевых по жребиям в Силоме пред Господем, у дверий скинии свидения. И скончаша делити землю.
Wọ̀nyí ni àwọn ilẹ̀ tí Eleasari àlùfáà, Joṣua ọmọ Nuni àti àwọn olórí ẹ̀yà agbo ilé Israẹli fi ìbò pín ní Ṣilo ní iwájú Olúwa ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé. Báyìí ni wọ́n parí pínpín ilẹ̀ náà.

< Книга Иисуса Навина 19 >