< Psalmów 88 >

1 Pieśń a psalm synów Korego przedniejszemu śpiewakowi na Machalat ku śpiewaniu, nauczający, (złożony)od Hemana Ezrahytczyka. Panie, Boże zbawienia mego! we dnie i w nocy wołam do ciebie.
Orin. Saamu ti àwọn ọmọ Kora. Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti mahalati leannoti. Maskili ti Hemani ará Esra. Olúwa, Ọlọ́run tí ó gbà mí là, ní ọ̀sán àti ní òru, mo kígbe sókè sí Ọ.
2 Niech przyjdzie przed oblicze twoje modlitwa moja; nakłoń ucha twego do wołania mego.
Jẹ́ kí àdúrà mi kí ó wá sí iwájú rẹ; dẹ etí rẹ sí igbe mi.
3 Bo nasycona jest utrapieniem dusza moja, a żywot mój przybliżył się aż do grobu. (Sheol h7585)
Nítorí ọkàn mi kún fún ìpọ́njú ọkàn mi sì súnmọ́ isà òkú. (Sheol h7585)
4 Poczytano mię między tych, którzy zstępują do dołu; byłem jako człowiek bez wszelakiej mocy.
A kà mí mọ́ àwọn tí wọ́n lọ sí ọ̀gbun ilẹ̀ èmi dàbí ọkùnrin tí kò ni agbára.
5 Policzony jestem między umarłymi; jestem jako pobici, leżący w grobie, na których więcej nie pamiętasz, którzy są od ręki twojej wytraceni.
A yà mí sọ́tọ̀ pẹ̀lú àwọn òkú bí ẹni tí a pa tí ó dùbúlẹ̀ ní ipò ikú, ẹni tí ìwọ kò rántí mọ́, ẹni tí a gé kúrò lára àwọn tí ìwọ ń tọ́jú.
6 Spuściłeś mię w dół najgłębszy, do najciemniejszego i najgłębszego miejsca.
Ìwọ tí ó fi mí sí kòtò jíjìn, ní ibi ọ̀gbun tó ṣókùnkùn.
7 Doległa mię zapalczywość twoja, a wszystkiemi nawałnościami twemi przytłoczyłeś mię. (Sela)
Ìbínú rẹ ṣubú lé mi gidigidi; ìwọ ti fi àwọn ìjì rẹ borí mi.
8 Dalekoś oddalił znajomych moich odemnie, którymeś mię bardzo obrzydził, a takiem zawarty, że mi nie lza wynijść.
Ìwọ tí gba ọ̀rẹ́ mi tí ó súnmọ́ mi kúrò lọ́wọ́ mi ìwọ sì sọ mi di ìríra sí wọn. A há mi mọ́, èmi kò sì le è jáde;
9 Oko moje zemdlało od utrapienia mego; wzywam cię, Panie! na każdy dzień, wyciągając do ciebie ręce moje.
ojú mi káàánú nítorí ìpọ́njú. Mo kígbe pè ọ́, Olúwa, ní gbogbo ọjọ́; mo na ọwọ́ mi jáde sí ọ.
10 Izali przed umarłymi cuda czynić będziesz? izali umarli powstaną, aby cię wysławiali? (Sela)
Ìwọ ó fi iṣẹ́ ìyanu rẹ hàn fún òkú bi? Àwọn òkú yóò ha dìde láti yìn ọ́ bí?
11 Izali opowiadane będzie w grobie miłosierdzie twoje? a prawda twoja w zginieniu?
A ó ha fi ìṣeun ìfẹ́ rẹ hàn ní ibojì bí, tàbí òtítọ́ rẹ ní ipò ìparun?
12 Izali poznają w ciemnościach cuda twoje? a sprawiedliwość twoję w ziemi zapamiętania?
A ha lè mọ iṣẹ́ ìyanu rẹ ní òkùnkùn bí àti òdodo rẹ ní ilẹ̀ ìgbàgbé?
13 Lecz ja, Panie! do ciebie wołam, a z poranku uprzedza cię modlitwa moja.
Ṣùgbọ́n mo kígbe sí ọ fún ìrànlọ́wọ́, Olúwa; ní òwúrọ̀ ni àdúrà mí wá sọ́dọ̀ rẹ.
14 Przeczże, o Panie! odrzucasz duszę moję, a zakrywasz oblicze twoje przedemną?
Olúwa, èéṣe tí ìwọ fi kọ̀ mí tí ìwọ fi ojú rẹ pamọ́ fún mi?
15 Jamci utrapiony, i prawie już umierający od gwałtu; ponoszę strachy twoje, i trwożę sobą.
Láti ìgbà èwe mi, ìṣẹ́ ń ṣẹ́ mi, èmi múra àti kú; nígbà tí ẹ̀rù rẹ bá ń bà mí, èmi di gbére-gbère.
16 Powstał przeciwko mnie srogi gniew twój, a strachy twoje wytraciły mię.
Ìbínú rẹ ti kọjá lára mi; ìbẹ̀rù rẹ ti gé mi kúrò.
17 Ogarniają mię jako woda przez cały dzień; otaczają mię gromadno.
Ní gbogbo ọjọ́ ni wọn yí mi ká bí ìkún omi; wọ́n mù mí pátápátá.
18 Oddaliłeś odemnie przyjaciela i towarzysza, a znajomym moim jestem jako w ciemności.
Ìwọ ti mú ọ̀rẹ́ àti olùfẹ́ mi kúrò lọ́dọ̀ mi; òkùnkùn sì jẹ́ ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ mi.

< Psalmów 88 >