< Psalmów 5 >

1 Przedniejszemu śpiewakowi na Nechylot psalm Dawidowy. Przyjmij, Panie! w uszy swe słowa moje, i wyrozumij doległości moje.
Fún adarí orin. Fún ohun èlò orin fífọn. Saamu ti Dafidi. Fi etí sí ọ̀rọ̀ mi, Olúwa, kíyèsi àròyé mi.
2 Słuchaj pilnie głosu wołania mego; królu mój, i Boże mój! boć się modlę tobie.
Fi etí sílẹ̀ sí igbe mi fún ìrànlọ́wọ́, ọba mi àti Ọlọ́run mi, nítorí ìwọ ni mo gba àdúrà sí.
3 Panie! rano usłysz głos mój; ranoć przedłożę modlitwę moję, i będę wyglądał pomocy.
Ní òwúrọ̀, Olúwa, ìwọ yóò gbọ́ ohùn mi; ní òwúrọ̀, èmi yóò gbé ẹ̀bẹ̀ mi sí iwájú rẹ̀ èmi yóò sì dúró ní ìrètí.
4 Albowiem ty, o Boże! nie kochasz się w nieprawości, a nie zmieszka z tobą złośnik.
Nítorí ìwọ kì í ṣe Ọlọ́run tí ó ní inú dídùn sí búburú; bẹ́ẹ̀ ni ẹni ibi kò le è bá ọ gbé.
5 Nieostoją się szaleni przed oczyma twemi: ty masz w nienawiści wszystkich, którzy broją nieprawości.
Àwọn agbéraga kò le è dúró níwájú rẹ̀. Ìwọ kórìíra gbogbo àwọn aṣebi;
6 Wygłubisz tych, którzy mówią kłamstwo; mężem krwawym i zdradliwym brzydzi się Pan.
ìwọ yóò pa àwọn tí ń ṣe èké run. Apani àti ẹni ẹ̀tàn ènìyàn ni Olúwa yóò kórìíra.
7 Ale ja w obfitości miłosierdzia twego wnijdę do domu twego, a pokłonię się w kościele twoim świętym, w bojaźni twojej.
Ṣùgbọ́n èmi, nípa títóbi àánú rẹ̀, èmi yóò wá sínú ilé rẹ̀; ní tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀ ni èmi yóò tẹríba sí ìhà tẹmpili mímọ́ rẹ̀.
8 Panie! prowadź mię w sprawiedliwości twojej dla nieprzyjaciół moich, a wyprostuj przed obliczem mojem drogę twoję.
Tọ́ mi, Olúwa, nínú òdodo rẹ, nítorí àwọn ọ̀tá mi, mú ọ̀nà rẹ tọ́ níwájú mi.
9 Bo niemasz nic szczerego w ustach ich; wnętrzności ich złośliwe, gardło ich jako grób otwarty, językiem swym pochlebiają.
Kò sí ọ̀rọ̀ kan ní ẹnu wọn tí a lè gbàgbọ́; ọkàn wọn kún fún ìparun. Ọ̀nà ọ̀fun wọn ni isà òkú tí ó ṣí sílẹ̀; pẹ̀lú ahọ́n wọn ni wọ́n ń sọ ẹ̀tàn.
10 Spustosz ich, o Boże! Niech upadną od rad swoich; dla wielkości przestępstwa ich rozpędź ich, ponieważ są odpornymi tobie.
Dá wọn lẹ́bi Ọlọ́run! Jẹ́ kí rìkíṣí wọn jẹ́ ìṣubú wọn. Lé wọn jáde nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀ṣẹ̀ wọn, nítorí wọ́n ti ṣọ̀tẹ̀ sí ọ.
11 A niechaj się rozweselą wszyscy, co ufają w tobie; na wieki niech wykrzykują, gdyż ich ty szczycić będziesz, i rozradują się w tobie, którzy miłują imię twoje.
Ṣùgbọ́n, jẹ́ kí gbogbo àwọn tí ó sádi ọ́ kí ó yọ̀; jẹ kí wọn máa kọrin fún ayọ̀ títí. Tan ààbò rẹ sórí wọn, àti àwọn tí ó fẹ́ràn orúkọ rẹ yóò máa yọ̀ nínú rẹ.
12 Albowiem ty, Panie! sprawiedliwemu błogosławić będziesz, a zastawisz go, jako tarczą, dobrotliwością twoją.
Dájúdájú, Olúwa, ìwọ bùkún olódodo; ìwọ fi ojúrere rẹ yí wọn ká bí asà.

< Psalmów 5 >