< Psalmów 12 >

1 Przedniejszemu śpiewakowi Seminit, pieśń Dawidowa. Ratuj, Panie! boć już niestaje miłosiernego, a wyginęli uprzejmi z synów ludzkich.
Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti ṣeminiti. Saamu ti Dafidi. Ràn wá lọ́wọ́, Olúwa, nítorí ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run kò sí mọ́; olóòtítọ́ tí pòórá kúrò láàrín àwọn ènìyàn.
2 Każdy mówi kłamstwo z bliźnim swoim: usty pochlebnemi, dwojakiem sercem mówią.
Olúkúlùkù ń parọ́ fún aládùúgbò rẹ̀; ètè èké wọn ń sọ ẹ̀tàn.
3 Niechajże Pan wytraci wszystkie wargi pochlebne, i język mówiący rzeczy wyniosłe.
Kí Olúwa kí ó gé ètè èké wọn àti gbogbo ahọ́n ìfọ́nnu
4 Którzy mówią: Językiem naszym przewiedziemy, wargi nasze za nami są, któż jest panem naszym?
tí ó wí pé, “Àwa ó borí pẹ̀lú ahọ́n wa; àwa ní ètè wa, ta ni ọ̀gá wa?”
5 Dla zniszczenia ubogich, i dla wołania nędznych teraz powstanę, mówi Pan; postawię w bezpieczności tego, na którego sidła stawiają.
“Nítorí ìnilára àwọn aláìlágbára àti ìkérora àwọn aláìní, Èmi yóò dìde nísinsin yìí,” ni Olúwa wí. “Èmi yóò dáàbò bò wọ́n lọ́wọ́ àwọn tí ń ṣe àrankàn wọn.”
6 Słowa Pańskie są słowa czyste, jako srebro wypławione w piecu glinianym, siedm kroć przelewane.
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì jẹ aláìlábùkù, gẹ́gẹ́ bí fàdákà tí a yọ́ nínú ìléru amọ̀, tí a sọ di mímọ́ nígbà méje.
7 Ty, Panie! zachowaj ich; strzeż ich od rodzaju tego aż na wieki.
Olúwa, ìwọ yóò pa wá mọ́ kí o sì gbà wá lọ́wọ́ àwọn ènìyàn wọ̀nyí títí láé.
8 Ze wszystkich stron niepobożni krążą, gdy wywyższeni bywają najpodlejsi między synami ludzkimi.
Àwọn ènìyàn búburú ń rin ìrìn fáàrí kiri nígbà tí wọn ń bọ̀wọ̀ fún òsì láàrín àwọn ènìyàn.

< Psalmów 12 >