< Liczb 26 >

1 I stało się po onej pladze, że mówił Pan do Mojżesza i do Eleazara, syna Aarona kapłana, mówiąc:
Lẹ́yìn àjàkálẹ̀-ààrùn Olúwa sọ fún Mose àti Eleasari ọmọ Aaroni, àlùfáà pé,
2 Policzcie poczet wszystkiego zgromadzenia synów Izraelskich, od tych, którzy mają dwadzieścia lat i wyżej, według domów ojców ich, każdego któryby mógł wynijść na wojnę z Izraela.
“Ka iye gbogbo àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọ́n; láti ẹni ogun ọdún àti jù bẹ́ẹ̀ lọ tí ó lè jà lójú ogun ní Israẹli.”
3 Tedy rzekł Mojżesz, i Eleazar kapłan do nich na polach Moabskich, nad Jordanem przeciw Jerychu, mówiąc:
Lórí pẹ̀tẹ́lẹ̀ ti Moabu pẹ̀lú Jordani tí ó kọjá Jeriko, Mose àti Eleasari àlùfáà sọ̀rọ̀ pẹ̀lú wọn ó wí pé,
4 Liczcie lud, od tych, którzy mają dwadzieścia lat i wyżej, jako był rozkazał Pan Mojżeszowi, i synom Izraelskim, gdy wyszli z ziemi Egipskiej.
“Ka iye àwọn ọkùnrin tí ó jẹ́ ọmọ-ogun ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.” Èyí ni àwọn ọmọ Israẹli tí ó jáde láti Ejibiti wá.
5 Ruben pierworodny Izraela: synowie Rubenowi Henoch, od którego poszedł dom Henochytów; Fallu, od którego dom Faalluitów;
Àwọn ọmọ Reubeni, àkọ́bí ọmọkùnrin Israẹli, láti ẹni ti ìdílé Hanoku, láti ọ̀dọ̀ ẹni tí ìdílé Hanoku ti jáde wá, láti ìdílé Pallu, láti ọ̀dọ̀ ẹni tí ìdílé àwọn ọmọ Pallu ti jáde wá;
6 I Hesron, od którego dom Hesronitów; Charmi, od którego dom Charmitów.
ti Hesroni, ìdílé àwọn ọmọ Hesroni; ti Karmi, ìdílé àwọn ọmọ Karmi.
7 Teć są domy Rubenitów; a było ich policzonych czterdzieści i trzy tysiące, siedem set i trzydzieści.
Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Reubeni; àwọn tí a sì kà nínú wọn jẹ́ ẹgbàá mọ́kànlélógún ó lé lẹ́gbẹ̀sán ó dín àádọ́rin.
8 A syn Fallów Elijab.
Àwọn ọmọkùnrin Pallu ni Eliabu,
9 Synowie zasię Elijabowi byli: Namuel, i Datan, i Abiron. A ci, Datan i Abiron, zacniejsi byli między zgromadzeniem, którzy się swarzyli z Mojżeszem i z Aaronem w spiknieniu Korego, gdy się zbuntowali przeciwko Panu.
àwọn ọmọkùnrin Elifelehu ni Nemueli àti Eliabu, Datani àti Abiramu. Èyí ni Datani àti Abiramu náà tí wọ́n ní òkìkí nínú ìjọ tí ó jẹ́ ọlọ̀tẹ̀ sí Mose àti Aaroni tí ó sì wà lára àwọn ẹgbẹ́ Kora nígbà tí wọ́n bá Olúwa jà.
10 I otworzyła ziemia usta swoje, a pożarła onych, i Korego, gdy zginęła ona rota, a pożarł ich ogień dwie cię i pięćdziesiąt mężów, którzy się stali na przykład innym;
Ilẹ̀ sì la ẹnu rẹ̀, ó sì gbé wọn mì pọ̀ pẹ̀lú Kora, nígbà tí ẹgbẹ́ rẹ̀ kú níbi tí iná ti run àwọn àádọ́ta lé nígba ọkùnrin. Tí wọ́n sì di àmì ìkìlọ̀.
11 Ale synowie Korego nie pomarli.
Àwọn ọmọ Kora, bí ó ti wù kí ó rí, wọn kò kú.
12 Synowie Symeonowi wedle domów swych, ci są: Namuel, od którego poszedł dom Namuelitów; Jamin, od którego dom Jaminitów; Jachin, od którego dom Jachinitów; Zare, od którego dom Zareitów;
Àwọn ọmọ ìran Simeoni bí ìdílé wọn: ti Nemueli, ìdílé Nemueli; ti Jamini, ìdílé Jamini; ti Jakini, ìdílé Jakini;
13 Saul, od którego dom Saulitów.
ti Sera, ìdílé Sera; tí Saulu, ìdílé Saulu.
14 Teć były domy Symeonitów, których było dwadzieścia i dwa tysiące i dwieście.
Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Simeoni, ẹgbẹ̀rún méjìlélógún ó lé igba ọkùnrin.
15 Synowie Gadowi według domów swych: Sefon, od którego poszedł dom Sefonitów; Aggi, od którego dom Aggitów; Suni, od którego dom Sunitów.
Àwọn ọmọ Gadi bí ìdílé wọn: ti Sefoni, ìdílé Sefoni; ti Haggi, ìdílé Haggi; ti Ṣuni, ìdílé Ṣuni;
16 Ozni, od którego dom Oznitów; Hery, od którego dom Herytów;
ti Osni, ìdílé Osni; ti Eri, ìdílé Eri;
17 Arod, od którego dom Arodytów; Aryjel, od którego dom Aryjelitów.
ti Arodi, ìdílé Arodi; ti Areli, ìdílé Areli.
18 Teć są domy synów Gadowych, według pocztów ich czterdzieści tysięcy i pięć set.
Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Gadi tí iye wọn sì jẹ́ ọ̀kẹ́ méjì ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta.
19 Synowie Judowi: Her, i Onan; ale pomarli Her i Onan w ziemi Chananejskiej.
Àwọn ọmọ Juda ni Eri àti Onani, ṣùgbọ́n Eri àti Onani kú ní ilẹ̀ Kenaani.
20 I byli synowie Judowi wedle domów swych: Sela, od którego poszedł dom Selaitów; Fares, od którego dom Faresytów; Zare, od którego dom Zarejczyków;
Àti àwọn ọmọ Juda gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn: ti Ṣela, ìdílé Ṣela; ti Peresi, ìdílé Peresi; ti Sera, ìdílé Sera.
21 Byli też synowie Faresowi: Hesron, od którego dom Hesronitów; Hamuel, od którego dom Hamuelitów.
Àwọn ọmọ Peresi: ti Hesroni, ìdílé Hesroni; ti Hamulu, ìdílé Hamulu.
22 Teć są domy Judy, według pocztów ich siedemdziesiąt tysięcy, i sześć, i pięć set.
Wọ̀nyí ni ìdílé Juda; gẹ́gẹ́ bí àwọn tí a kà nínú wọn tí iye wọn sì jẹ́ ẹgbàá méjìdínlógójì ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta.
23 Synowie Isascharowi według domów swych: Tola, od którego dom Tolaitów; Fua, od którego dom Fuaitów;
Àwọn ọmọ Isakari gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn: ti Tola, ìdílé Tola; ti Pufa, ìdílé Pufa;
24 Jasub, od którego dom Jasubitów; Semram, od którego dom Semramitów.
ti Jaṣubu, ìdílé Jaṣubu; ti Ṣimroni, ìdílé Ṣimroni.
25 Teć są domy Isascharowe, wedle pocztów ich sześćdziesiąt tysięcy i cztery, i trzy sta.
Wọ̀nyí ni ìdílé Isakari gẹ́gẹ́ bí àwọn tí a kà nínú wọn tí iye wọn sì jẹ́ ẹgbàá méjìlélọ́gbọ̀n ó lé ọ̀ọ́dúnrún.
26 Synowie Zabulonowi według domów swych: Zared, od którego dom Zaredczyków; Elon, od którego dom Elonitów; Jaleel, od którego dom Jaleelitów.
Àwọn ọmọ Sebuluni gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn: ti Seredi, ìdílé Seredi; ti Eloni, ìdílé Eloni; ti Jaleeli, ìdílé Jaleeli.
27 A teć są domy Zabulonitów, według pocztów ich sześćdziesiąt tysięcy i pięć set.
Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Sebuluni gẹ́gẹ́ bí àwọn tí a kà nínú wọn tí iye wọn sì jẹ́ ọ̀kẹ́ mẹ́ta ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta.
28 Synowie Józefowi według domów swych: Manases i Efraim.
Àwọn ọmọ Josẹfu gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn; Manase àti Efraimu.
29 Synowie Manasesowi: Machir, od którego dom Machirytów; a Machir spłodził Galaada, od Galaada dom Galaadytów.
Àwọn ọmọ Manase: ti Makiri, ìdílé Makiri (Makiri sì bí Gileadi); ti Gileadi, ìdílé àwọn ọmọ Gileadi.
30 Ci są synowie Galaadowi: Jezer, od którego dom Jezerytów; Chelek, od którego dom Chelekitów;
Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Gileadi: ti Ieseri, ìdílé Ieseri; ti Heleki, ìdílé Heleki
31 I Asryjel, od którego dom Asryjelitów; i Sechem, od którego dom Sechemitów;
àti ti Asrieli, ìdílé Asrieli; àti ti Ṣekemu, ìdílé Ṣekemu;
32 I Semida, od którego dom Semidaitów; i Chefer, od którego dom Cheferytów.
àti Ṣemida, ìdílé àwọn ọmọ Ṣemida; àti ti Heferi, ìdílé àwọn ọmọ Heferi.
33 A Salfaad, syn Cheferów, nie miał synów, tylko córki, a imiona córek Salfaadowych: Machla, i Noa, Hegla, Melcha, i Tersa.
(Selofehadi ọmọ Heferi kò sì ni ọmọkùnrin, bí kò ṣe ọmọbìnrin; orúkọ àwọn ọmọbìnrin ni Mahila, Noa, àti Hogla, Milka àti Tirsa).
34 Teć są domy Manasesowe, a poczet ich pięćdziesiąt i dwa tysiące i siedem set.
Wọ̀nyí ni ìdílé Manase tí iye wọn sì jẹ́ ẹgbàá mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin.
35 Synowie zaś Efraimowi według domów swych: Sutala, od którego dom Sutalitów; Becher, od którego dom Becherytów; Techen, od którego dom Techenitów.
Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Efraimu gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn: láti ọ̀dọ̀ Ṣutelahi, ìdílé àwọn ọmọ Ṣutelahi; ti Bekeri, ìdílé àwọn ọmọ Bekeri; ti Tahani, ìdílé àwọn ọmọ Tahani.
36 A ci są synowie Sutalego: Heran, od którego dom Heranitów.
Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Ṣutelahi: ti Erani, ìdílé àwọn ọmọ Erani.
37 Teć są domy synów Efraimowych, według pocztów ich trzydzieści tysięcy i dwa, i pięć set. Ci są synowie Józefowi według domów swych.
Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Efraimu, àwọn tí a kà nínú wọn sì jẹ́ ẹgbàá mẹ́rìndínlógún ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Josẹfu gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn.
38 A synowie Benjaminowi według domów swych, ci są: Bela, od którego dom Belitów; Asbel, od którego dom Asbelitów; Achiram, od którego dom Achiramitów;
Àwọn ọmọ Benjamini gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn nìyìí: tí Bela, ìdílé àwọn ọmọ Bela; ti Aṣbeli, ìdílé àwọn ọmọ Aṣbeli; ti Ahiramu, ìdílé àwọn ọmọ Ahiramu;
39 Sufam, od którego dom Sufamitów; Hufam, od którego dom Hufamitów.
ti Ṣufamu, ìdílé àwọn ọmọ Ṣufamu; ti Hufamu, ìdílé àwọn ọmọ Hufamu.
40 Byli też synowie Beli: Hereda i Noemana; z Hereda dom Heredytów, a z Noemana dom Noemanitów.
Àwọn ọmọ Bela ní ipasẹ̀ Ardi àti Naamani nìyìí: ti Ardi, ìdílé àwọn ọmọ Ardi; ti Naamani, ìdílé àwọn ọmọ Naamani.
41 Cić są synowie Benjaminowi, według domów ich, a poczet ich czterdzieści i pięć tysięcy i sześć set.
Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Benjamini; gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn; àti àwọn tí a kà nínú wọn jẹ́ ẹgbàá méjìlélógún ó lé ẹgbẹ̀jọ.
42 Synowie zaś Danowi według domów swych: Sucham, od którego dom Suchamitów. Teć były domy Danowe według familii ich.
Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Dani gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn: ti Ṣuhamu, ìdílé àwọn ọmọ Ṣuhamu. Wọ̀nyí ni ìdílé Dani gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn.
43 Wszystkie domy Suchamitów według pocztów ich sześćdziesiąt i cztery tysiące i cztery sta.
Gbogbo ìdílé àwọn ọmọ Ṣuhamu, gẹ́gẹ́ bí àwọn tí a kà nínú wọn jẹ́ ẹgbàá méjìlélọ́gbọ̀n ó lé irinwó.
44 Synowie Aserowi według domów swych byli: Jemna, od którego dom Jemnitów; Iswi, od którego dom Iswitów; Beryja, od którego dom Berytów.
Ti àwọn ọmọ Aṣeri gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn: ti Imina, ìdílé àwọn ọmọ Imina; ti Iṣfi, ìdílé àwọn ọmọ Iṣfi; ti Beriah, ìdílé àwọn ọmọ Berii.
45 Synowie Beryjego: Heber, od którego dom Heberytów; Melchyjel, od którego dom Melchyjelitów.
Ti àwọn ọmọ Beriah: ti Heberi, ìdílé àwọn ọmọ Heberi; ti Malkieli, ìdílé àwọn ọmọ Malkieli.
46 A imię córki Aserowej było Sara.
(Orúkọ ọmọ Aṣeri obìnrin nì jẹ́ Sera.)
47 Te są domy synów Aserowych, według pocztów ich pięćdziesiąt i trzy tysiące i cztery sta.
Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Aṣeri gẹ́gẹ́ bí àwọn tí a kà nínú wọn jẹ́ ẹgbàá mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ó lé egbèje.
48 Synowie Neftalimowi według domów swych: Jachsel, od którego dom Jachselitów; Guni, od którego dom Gunitów; Jesser, od którego dom Jesserytów.
Ti àwọn ọmọ Naftali gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn: ti Jasieli, ìdílé àwọn ọmọ Jaseeli: ti Guni, ìdílé àwọn ọmọ Guni;
49 Selem, od którego dom Selemitów.
ti Jeseri, ìdílé àwọn ọmọ Jeṣeri; ti Ṣillemu, ìdílé àwọn ọmọ Ṣillemu.
50 Teć są domy Neftalimowe, według familii ich, a poczet ich czterdzieści i pięć tysięcy i cztery sta.
Wọ̀nyí ni ìdílé ti Naftali gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn, àwọn tí a kà nínú wọn jẹ́ ẹgbàá méjìlélógún ó lé egbèje.
51 Tać jest liczba synów Izraelskich, sześć kroć sto tysięcy i tysiąc, siedem set i trzydzieści.
Àpapọ̀ iye tí a kà nínú àwọn ọmọ Israẹli jẹ́ ọgbọ̀n ọ̀kẹ́ ó lé ẹgbẹ̀sán dín làádọ́rin.
52 Zatem rzekł Pan do Mojżesza, mówiąc:
Olúwa sọ fún Mose pé,
53 Między te podzielicie tę ziemię w dziedzictwo według liczby imion.
“Ilẹ̀ náà gbọdọ̀ jẹ́ pínpín fún wọn gẹ́gẹ́ bí ogún wọn gẹ́gẹ́ bí iye orúkọ wọn.
54 Większej liczbie więcej dziedzictwa dasz, a mniejszej mniejsze dziedzictwo dasz; każdemu według pocztów policzonych jego będzie dane dziedzictwo jego.
Fún àwọn ọ̀pọ̀ ni kí ìwọ ó fún ní ogún ìlú púpọ̀ àti fún àwọn tí ó kéré ni kí ìwọ ó fi kékeré fún, ẹnìkọ̀ọ̀kan gbọdọ̀ gba ogún ìbí tirẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ènìyàn tí a kọ.
55 Wszakże losem niech będzie rozdzielona ziemia; według imion pokoleń ojców swych dziedzictwo brać będą.
Rí dájú pé ilẹ̀ yìí gbọdọ̀ jẹ́ fífi ìbò pín gẹ́gẹ́ bí wọn sì ti pọ̀ tó. Gẹ́gẹ́ bí orúkọ ẹ̀yà àwọn baba wọn ni kí wọn kí ó ni í.
56 Losem rozdzielone będzie dziedzictwo jej bądź ich wiele bądź mało będzie.
Olúkúlùkù ogún ìní ni a gbọdọ̀ fi ìbò pín gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti pọ̀ tó láàrín ńlá àti kékeré.”
57 Ci zasię są policzeni z Lewitów według domów swych: Gerson, od którego dom Gersonitów; Kaat, od którego dom Kaatytów; Merary, od którego dom Merarytów.
Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Lefi tí a kà nínú wọn gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn: ti Gerṣoni, ìdílé àwọn ọmọ Gerṣoni; ti Kohati, ìdílé àwọn ọmọ Kohati; ti Merari, ìdílé àwọn ọmọ Merari.
58 Teć są domy Lewi: dom Libnitów, dom Hebronitów, dom Moholitów, dom Musytów, dom Korytów; a Kaat spłodził Amrama.
Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Lefi; ìdílé àwọn ọmọ Libni, ìdílé àwọn ọmọ Hebroni, ìdílé àwọn ọmọ Mahili, ìdílé àwọn ọmọ Muṣi, ìdílé àwọn ọmọ Kora. (Kohati ni baba Amramu,
59 A imię żony Amramowej było Jochabod, córka Lewiego, która mu się urodziła w Egipcie; ta Amramowi urodziła Aarona, i Mojżesza, i Maryją, siostrę ich.
orúkọ aya Amramu sì ń jẹ́ Jokebedi, ọmọbìnrin Lefi, tí ìyá rẹ̀ bí fún Lefi ní Ejibiti. Òun sì bí Aaroni, Mose, àti Miriamu arábìnrin wọn fún Amramu.
60 Aaronowi też urodzili się Nadabi i Abiju, Eleazar i Itamar.
Aaroni ni baba Nadabu àti Abihu, Eleasari àti Itamari.
61 Ale pomarli Nadab i Abiju, gdy ofiarowali ogień obcy przed Panem.
Ṣùgbọ́n Nadabu àti Abihu kú, nígbà tí wọ́n rú ẹbọ níwájú Olúwa nígbà tí wọ́n mú iná àjèjì wá.)
62 A była liczba ich dwadzieścia i trzy tysiące, wszystkich mężczyzn urodzonych od miesiąca i wyżej; jednak nie byli policzeni między syny Izraelskie, bo im nie dano dziedzictwa między syny Izraelskimi.
Gbogbo àwọn ọmọkùnrin Lefi láti oṣù kan àti ju bẹ́ẹ̀ lọ ẹgbẹ̀rún méjìlélógún ó lé lẹ́gbẹ̀rún. Wọn kò ka wọ́n mọ́ àwọn ọmọ Israẹli tókù nítorí tí wọ́n kò gba ogún ìní lára wọn.
63 Ci policzeni byli od Mojżesza i Eleazara kapłana, którzy policzyli syny Izraelskie na polach Moabskich, nad Jordanem przeciw Jerychu.
Àwọn wọ̀nyí ni Mose àti Eleasari àlùfáà kà nígbà tí wọ́n ka àwọn ọmọ Israẹli ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu lẹ́bàá odò Jordani létí Jeriko.
64 A między tymi nie był żaden z onych policzonych od Mojżesza i Aarona kapłana, gdy liczyli syny Izraelskie na puszczy Synaj;
Kò sí ẹnìkan nínú àwọn tí Mose àti Aaroni àlùfáà kà nígbà tí wọ́n ka àwọn ọmọ Israẹli ní aginjù Sinai.
65 Bo rzekł był Pan o nich: Śmiercią pomrą na puszczy; a nie został żaden z nich, oprócz Kaleba, syna Jefunowego, i Jozuego, syna Nunowego.
Nítorí Olúwa ti sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé kíkú ni wọn yóò kú sí aginjù, kò sì sí ẹnìkankan nínú wọn tí kò kú àfi Kalebu ọmọ Jefunne, àti Joṣua ọmọ Nuni.

< Liczb 26 >