< Nahuma 2 >

1 Ciągnie skażyciel przeciw tobie, o Niniwe! opatrz miejsca obronne, wyglądaj na drogę, zmocnij biodra, a bardzo umocnij siłę twoję;
Àwọn apanirun ti dìde sí ọ, ìwọ Ninefe. Pa ilé ìṣọ́ mọ́, ṣọ́ ọ̀nà náà, di àmùrè, ẹ̀gbẹ́ rẹ kí ó le múra gírí.
2 Bo Pan odwrócił pychę Jakóbową, jako pychę Izraelową, przeto, że ich wyniszczyli skażyciele, a latorośle ich popsowali.
Olúwa yóò mú ọláńlá Jakọbu padà sípò gẹ́gẹ́ bí ọláńlá Israẹli bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn apanirun ti pa ibẹ̀ run, tí wọ́n sì ba ẹ̀ka àjàrà wọn jẹ́.
3 Tarcza mocarzy jego czerwona, rycerstwo jego szarłatem odziane, wozy jego jako pochodnie gorejące iskrzyć się będą w dzień potykania jego, a jodły straszne trząść się będą.
Asà àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ sì di pupa; àwọn ológun wọn sì wọ aṣọ òdòdó. Idẹ tí ó wà lórí kẹ̀kẹ́ ogun ń kọ mọ̀nàmọ́ná ní ọjọ́ tí a bá pèsè wọn sílẹ̀ tán; igi firi ni a ó sì mì tìtì.
4 Wozy po ulicach grzmieć i po rynku skrzypieć będą; na wejrzeniu będą jako pochodnie, a jako błyskawice biegać będą.
Àwọn kẹ̀kẹ́ ogun yóò ya bo àwọn pópónà, wọn yóò sì máa sáré síwá àti sẹ́yìn ní àárín ìgboro. Wọn sì dàbí ètùfù iná; tí ó sì kọ bí i mọ̀nàmọ́ná.
5 Szykuje mocarzy swoich, ale jednak upadną w szyku swym; pospieszy się do murów, jakoby tam zgotowana była obrona.
Ninefe yóò ṣe àṣàrò àwọn ọlọ́lá rẹ̀; síbẹ̀ wọ́n ń kọsẹ̀ ní ojú ọ̀nà wọn; wọn sáré lọ sí ibi odi rẹ̀, a ó sì pèsè ààbò rẹ̀.
6 Bramy się przy rzekach otworzą, a kościół się rozpłynie;
A ó ṣí ìlẹ̀kùn àwọn odò wọ̀n-ọn-nì sílẹ̀, a ó sì mú ààfin náà di wíwó palẹ̀.
7 A Chusab pojmana będąc zawiedziona będzie, a służebnice jej prowadzić ją będą, hucząc jako gołębica a bijąc się w piersi swe.
A pa á láṣẹ pé ìlú náà, èyí tí a ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ ni a ó sì kó ní ìgbèkùn lọ. A ó sì mú un gòkè wá àti àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀ yóò kérora bí ti ẹyẹ àdàbà, wọn a sì máa lu àyà wọn.
8 A aczkolwiek Niniwe było jako sadzawka wód od początku swego, wszakże już sami uciekają; a choć kto rzecze: Stójcie, stójcie! wszakże się nikt nie obejrzy.
Ninefe dàbí adágún omi, tí omi rẹ̀ sì ń gbẹ́ ẹ lọ. “Dúró! Dúró!” ni wọ́n ó máa kígbe, ṣùgbọ́n ẹnìkankan kì yóò wo ẹ̀yìn.
9 Rozchwyćcież srebro, rozchwyćcież złoto, i niezmierne bogactwa, i cokolwiek najkosztowniejszego ze wszystkich klejnotów drogich.
“Ẹ kó ìkógun fàdákà! Ẹ kó ìkógun wúrà! Ìṣúra wọn ti kò lópin náà, àti ọrọ̀ kúrò nínú gbogbo ohun èlò ti a fẹ́!”
10 Wyplundrowane i wybrane będzie, owszem, do szczętu spustoszone będzie; serce się rozpłynie, kolano o kolano tłuc się będzie, i boleść na wszystkich biodrach będzie, a oblicza wszystkich poczernieją.
Òun ti ṣòfò, ó si di asán, ó sì di ahoro: ọkàn pami, eékún ń lu ara wọn, ìrora púpọ̀ sì wà nínú gbogbo ẹgbẹ́ àti ojú gbogbo wọ́n sì rẹ̀wẹ̀sì.
11 Gdzież jest jaskinia lwów, i pastwisko lwiąt? gdzie chodził lew, lew, mówię, i lwica, a nie było nikogo, ktoby je przestraszył.
Níbo ni ihò àwọn kìnnìún wà àti ibi ìjẹun àwọn ọmọ kìnnìún, níbi tí kìnnìún, àní abo kìnnìún tí ń rìn, àti ọmọ kìnnìún, láìsí ohun ìbẹ̀rù.
12 Lew, który dostatkiem chwytał lwiętom swoim i zaduszał dla lwic swoich, który napełniał łupem jaskinie swoje, a obłowem łożyska swoje.
Kìnnìún tipa ọ̀pọ̀lọpọ̀ fún àwọn ọmọ rẹ̀, ó sì fún un ẹran ọdẹ ní ọrùn pa fún àwọn abo kìnnìún rẹ̀, ó sì fi ohun pípa kún ibùgbé rẹ̀ àti ihò rẹ̀ fún ohun ọdẹ.
13 Otom Ja przeciwko tobie, mówi Pan zastępów, a popalę na proch wozy twoje, a miecz pożre lwięta twoje; i wykorzenię z ziemi łup twój, a nie będzie więcej słyszany głos posłów twoich.
“Kíyèsi i èmi dojúkọ ọ́,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí. “Èmi yóò sì fi kẹ̀kẹ́ rẹ̀ wọ̀n-ọn-nì jóná nínú èéfín, idà yóò sì jẹ ọmọ kìnnìún rẹ̀ wọ̀n-ọn-nì run. Èmi yóò sì ké ohun ọdẹ rẹ kúrò lórí ilẹ̀ ayé. Ohùn àwọn ìránṣẹ́ rẹ ni a kì yóò sì tún gbọ́ mọ́.”

< Nahuma 2 >