< Jeremiasza 45 >

1 Słowo, które mówił Jeremijasz prorok do Barucha, syna Neryjaszowego, gdy pisał te słowa w księgi z ust Jeremijaszowych roku czwartego za Joakima, syna Jozyjasza, króla Judzkiego, mówiąc:
Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Jeremiah wòlíì sọ fún Baruku ọmọ Neriah ní ọdún kẹrin ti Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda. Lẹ́yìn tí Baruku ti kọ sínú ìwé kíká àwọn ọ̀rọ̀ tí Jeremiah ti ń sọ:
2 Tak mówi Pan, Bóg Izraelski, o tobie, Baruchu!
“Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ fún ọ, Baruku.
3 Rzekłeś: Biada mnie teraz! bo Pan przyczynia żałości do bolaści mojej; upracowałem się w wzdychaniu mojem, a odpoczynku nie znajduję.
Ìwọ wí pé, ‘Ègbé ni fún mi! Olúwa ti fi ìbànújẹ́ kún ìrora mi, àárẹ̀ mú mi nínú ẹ̀dùn mi, èmi kò sì rí ìsinmi.’”
4 Tak rzeczesz do niego: Tak mówi Pan: Oto com zbudował, Ja rozwalam, a com wszczepił, Ja wyrywam, i tę wszystkę ziemię.
Olúwa wí pé sọ èyí fún un, “Èyí ni Ọlọ́run sọ: ‘Èyí tí èmi ti kọ́ ni èmi yóò wò lulẹ̀, àti èyí tí èmi ti gbìn ni èmi yóò fàtu, àní ní orí gbogbo ilẹ̀.
5 A ty sobie szukasz rzeczy wielkich? Nie szukaj. Bo oto Ja przywiodę złe na wszelkie ciało, mówi Pan: ale tobie dam duszę twoję w korzyści na wszelkich miejscach, dokądkolwiek pójdziesz.
Ṣé ìwọ sì ń wá ohun títóbi fún ara rẹ? Nítorí náà, má ṣe wá wọn. Èmi yóò mú ibi wá sí orí àwọn ènìyàn gbogbo ni Olúwa wí, ṣùgbọ́n níbikíbi tí ìwọ bá lọ ni èmi yóò jẹ́ kí o sá àsálà pẹ̀lú ẹ̀mí rẹ.’”

< Jeremiasza 45 >