< Jeremiasza 21 >

1 Słowo, które się stało do Jeremijasza od Pana, gdy do niego król Sedekijasz posłał Fassura, syna Malchyjaszowego, i Sofonijasza, syna Maasejaszowego, kapłana, aby rzekli:
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Jeremiah wá nígbà tí ọba Sedekiah rán Paṣuri ọmọ Malkiah àti àlùfáà Sefaniah ọmọ Maaseiah sí i; wọ́n wí pé:
2 Poradź się, proszę, o nas Pana; bo Nabuchodonozor, król Babiloński, walczy przeciwko nam: owa snać uczyni Pan z nami według wszystkich dziwnych spraw swoich, żeby odciągnął od nas.
“Wádìí lọ́wọ́ Olúwa fún wa nítorí Nebukadnessari ọba Babeli ń kọlù wá. Bóyá Olúwa yóò ṣe ìyanu fún wa gẹ́gẹ́ bí ti àtẹ̀yìnwá, kí ó sì yípadà kúrò lọ́dọ̀ wa.”
3 I rzekł Jeremijasz do nich: Tak powiedzcie Sedekijaszowi:
Ṣùgbọ́n Jeremiah dáhùn wí pé, “Sọ fún Sedekiah,
4 Tak mówi Pan, Bóg Izraelski: Oto Ja odwrócę naczynia wojenne, które są w rękach waszych, i któremi wy walczycie przeciw królowi Babilońskiemu, i Chaldejczykom, którzy was oblegli około muru, i zgromadzę ich w pośrodek miasta tego.
‘Èyí ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli wí, Èmi fẹ́ kọjú idà tí ó wà lọ́wọ́ yín sí yín, èyí tí ẹ̀ ń lò láti bá ọba àti àwọn ará Babeli tí wọ́n wà lẹ́yìn odi jà, Èmi yóò sì kó wọn jọ sínú ìlú yìí.
5 A Ja sam walczyć będę przeciwko wam ręką wyciągnioną i ramieniem możnem, a to w gniewie, i w popędliwości, i w zapalczywości wielkiej;
Èmi gan an yóò sì bá yín jà pẹ̀lú ohun ìjà olóró nínú ìbínú àti ìrunú líle.
6 I uderzę obywateli tego miasta, tak, że i ludzie i bydlęta morem wielkim pomrą.
Èmi yóò sì lu gbogbo ìlú yìí, ènìyàn àti ẹranko, gbogbo wọn ni àjàkálẹ̀-ààrùn yóò kọlù tí wọn yóò sì kú.
7 A potem, tak mówi Pan, podam Sedekijasza, króla Judzkiego, i sługi jego, i lud, to jest tych, którzy pozostaną w tem mieście po morze, i po mieczu, i po głodzie, w rękę Nabuchodonozora, króla Babilońskiego i w rękę nieprzyjaciół ich, a tak w rękę szukających duszy ich, który ich pobije ostrzem miecza: nie przepuści im, ani im sfolguje, ani się zmiłuje.
Olúwa sọ pé lẹ́yìn èyí, èmi yóò fi Sedekiah ọba Juda, àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, àti àwọn ènìyàn, àti àwọn tí ó kù ní ìlú yìí lọ́wọ́ àjàkálẹ̀-ààrùn àti lọ́wọ́ idà, àti lọ́wọ́ ìyàn; èmi yóò fi wọ́n lé Nebukadnessari ọba Babeli lọ́wọ́, àti lé ọwọ́ àwọn ọ̀tá wọn, àti lé ọwọ́ àwọn tí ń lépa ẹ̀mí wọn, òun yóò sì fi ojú idà pa wọ́n, kì yóò sì dá wọn sí, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò ní ìyọ́nú tàbí ṣàánú wọn.’
8 Przetoż rzecz do ludu tego: Tak mówi Pan: Oto ja kładę przed wami drogę żywota i drogę śmierci.
“Síwájú sí i, sọ fún àwọn ènìyàn, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó sọ: Wò ó, Èmi ń fi ọ̀nà ìyè àti ikú hàn yín.
9 Ktokolwiek zostanie w tem mieście, zginie od miecza, albo od głodu, albo od moru: ale kto wyjdzie i poda się Chaldejczykom, którzy was oblegli, pewnie żyw zostanie, i będzie mu dusza jego w korzyści.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá dúró sí ìlú yìí yóò ti ipa idà, ìyàn tàbí àjàkálẹ̀-ààrùn kú. Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá jáde tí ó sì jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún àwọn Babeli tí ó ń lépa yín yóò sì yè. Òun yóò sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ̀.
10 Bom obrócił oblicze moje przeciwko temu miastu ku złemu, a nie ku dobremu, mówi Pan. W rękę króla Babilońskiego podane będzie, i spali je ogniem.
Mo ti pinnu láti jẹ ìlú yìí ní yà, ni Olúwa wí. A ó sì gbé e fún ọba Babeli, yóò sì run ún pẹ̀lú iná.’
11 Ale domowi króla Judzkiego rzecz: Słuchajcie słowa Pańskiego.
“Ẹ̀wẹ̀, wí fún ìdílé ọba Juda pé, ‘Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa.
12 O domie Dawidowy! Tak mówi Pan: Odprawujcie sąd każdego poranku, a wyrywajcie uciśnionego z ręki gwałtownika, by snać nie wyszła jako ogień zapalczywość moja, a nie gorzała, tak, żeby nie był, ktoby ugasił dla złości spraw waszych.
Ilé Dafidi èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa sọ: “‘Ṣe ìdájọ́ tí ó tọ́ ní àràárọ̀; yọ ọ́ kúrò lọ́wọ́ ẹni tí ó ń ni í lára ẹni tí a ti jà lólè bí bẹ́ẹ̀ kọ́ ìbínú mi yóò jáde síta, yóò sì jó bí iná. Nítorí ibi tí a ti ṣe yóò sì jó láìsí ẹni tí yóò pa á.
13 Otom Ja przeciwko tobie, która mieszkasz w tej dolinie, jako skała w tej równinie, mówi Pan, którzy mówicie: Któż przyciągnie na nas? a kto wnijdzie do przybytków naszych?
Mo kẹ̀yìn sí ọ, Jerusalẹmu, ìwọ tí o gbé lórí àfonífojì lórí òkúta tí ó tẹ́jú, ni Olúwa wí. Ìwọ tí o ti wí pé, “Ta ni ó le dojúkọ wá? Ta ni yóò wọ inú ibùgbé wa?”
14 Bo was nawiedzę według owocu spraw waszych, mówi Pan; a rozniecę ogień w lesie twoim, który pożre wszystko około niego.
Èmi yóò jẹ ọ ní ìyà gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀ ni Olúwa wí. Èmi yóò mú kí iná jó ilé rẹ̀; yóò si jó gbogbo ohun tí ó wà ní àyíká rẹ.’”

< Jeremiasza 21 >