< Ezdrasza 2 >

1 A cić są ludzie onej krainy, którzy wyszli z pojmania i z niewoli, w którą ich był zaprowadził Nabuchodonozor, król Babiloński, do Babilonu, a wrócili się do Jeruzalemu i do Judy, każdy do miasta swego.
Lákòókò náà, wọ̀nyí ni àwọn ènìyàn agbègbè Juda tí ó gòkè wá láti ìgbèkùn láàrín àwọn tí a kó lọ, ẹni tí Nebukadnessari ọba Babeli ti fi agbára mú ní ìgbèkùn lọ sí Babeli (wọ́n padà sí Jerusalẹmu àti Juda, olúkúlùkù sí ìlú rẹ̀.
2 Którzy przyszli z Zorobabelem, z Jesuą, Nehemijaszem, Sarajaszem, Rehelijaszem, Mardocheuszem, Bilsanem, Misparem Bigwajem, Rechumem, i Baaną. A poczet ludu Izraelskiego ten był:
Àwọn wọ̀nyí bá Serubbabeli, Jeṣua, Nehemiah, Seraiah, Reelaiah, Mordekai, Bilṣani, Mispari, Bigfai, Rehumu àti Baanah wá). Iye àwọn ọkùnrin àwọn ènìyàn Israẹli.
3 Synów Farosowych dwa tysiące sto siedmdziesiąt i dwa;
Àwọn ọmọ Paroṣi jẹ́ ẹgbàá ó lé méjìléláàádọ́sàn-án
4 Synów Sefatyjaszowych trzy sta siedmdziesiąt i dwa;
Ṣefatia jẹ́ òjìdínnírinwó ó lé méjìlá
5 Synów Arachowych siedm set siedmdziesiąt i pięć;
Arah jẹ́ ẹgbẹ̀rin ó dín mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n
6 Synów Pachat Moabowych, synów Jesui Joabowych dwa tysiące ośm set i dwanaście;
Pahati-Moabu (láti ipasẹ̀ àwọn ọmọ Jeṣua àti Joabu) jẹ́ ẹgbẹ̀rún méjì àti ẹgbẹ̀rin lé méjìlá
7 synów Elamowych tysiąc dwieście pięćdziesiąt i cztery;
Elamu jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀fà ó lé mẹ́rin
8 Synów Zatuowych dziewięć set i czterdzieści i pięć;
Sattu jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rún ó lé márùn-ún
9 Synów Zachajowych siedm set i sześćdziesiąt;
Sakkai jẹ́ òjìdínlẹ́gbẹ̀rin
10 Synów Bani sześć set czterdzieści i dwa;
Bani jẹ́ òjìlélẹ́gbẹ̀ta ó lé méjì
11 Synów Bebajowych sześć set dwadzieścia i trzy.
Bebai jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó lé mẹ́tàlélógún
12 Synów Azgadowych tysiąc dwieście dwadzieścia i dwa.
Asgadi jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé méjìlélógún
13 Synów Adonikamowych sześć set sześćdziesiąt i sześć;
Adonikami jẹ́ ọ̀tàlélẹ́gbẹ̀ta ó lé mẹ́fà
14 Synów Bigwajowych dwa tysiące pięćdziesiąt i sześć;
Bigfai jẹ́ ẹgbàá ó lé mẹ́rìndínlọ́gọ́ta
15 Synów Adynowych cztery sta pięćdziesiąt i cztery.
Adini jẹ́ àádọ́ta lé ní irinwó ó lé mẹ́rin
16 Synów Aterowych, co poszli z Ezechyjasza, dziewięćdziesiąt i ośm;
Ateri (nípasẹ̀ Hesekiah) jẹ́ méjìdínlọ́gọ́run
17 Synów Besajowych trzy sta dwadzieścia i trzy.
Besai jẹ́ ọrùndínnírinwó ó lé mẹ́ta
18 Synów Jory sto i dwanaście;
Jora jẹ́ méjìléláàádọ́fà
19 Synów Hasumowych dwieście dwadzieścia i trzy.
Haṣumu jẹ́ igba ó lé mẹ́tàlélógún
20 Synów Gibbarowych dziewięćdziesiat i pięć;
Gibbari jẹ́ márùndínlọ́gọ́rùn.
21 Synów z Betlehemu sto dwadzieścia i trzy;
Àwọn ọmọ Bẹtilẹhẹmu jẹ́ mẹ́tàlélọ́gọ́fà
22 Mężów z Netofatu pięćdziesiąt i sześć;
Netofa jẹ́ mẹ́rìndínlọ́gọ́ta
23 Mężów z Anatotu sto dwadzieścia i ośm;
Anatoti jẹ́ méjìdínláàádóje
24 Synów z Azmawetu czterdzieści i dwa;
Asmafeti jẹ́ méjìlélógójì
25 Synów z Karyjatyjarymu, z Kafiry i z Beerotu siedm set i czterdzieści i trzy;
Kiriati-Jearimu, Kefira àti Beeroti jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó lé mẹ́ta
26 Synów z Ramy i z Gabaa sześć set dwadzieścia i jeden;
Rama àti Geba jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó lé mọ́kànlélógún
27 Mężów z Machmas sto dwadzieścia i dwa;
Mikmasi jẹ́ méjìlélọ́gọ́fà
28 Mężów z Betela i z Haj dwieście dwadzieścia i trzy;
Beteli àti Ai jẹ́ igba ó lé mẹ́tàlélógún
29 Synów z Nebo pięćdziesiąt i dwa;
Nebo jẹ́ méjìléláàádọ́ta
30 Synów Magbisowych sto pięćdziesiąt i sześć;
Magbiṣi jẹ́ mẹ́rìndínlọ́gọ́jọ
31 Synów Elama drugiego tysiąc dwieście pięćdziesiąt i cztery;
Elamu mìíràn jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé mẹ́rìnléláàádọ́ta
32 Synów Harymowych trzy sta i dwadzieścia;
Harimu jẹ́ ọ̀rìndínnírinwó.
33 Synów Lodowych, Hadydowych, i Onowych siedm set dwadzieścia i pięć;
Lodi, Hadidi àti Ono jẹ́ ọ̀rìndínlẹ́gbẹ̀rin ó lé márùn-ún
34 Synów Jerechowych trzy sta czterdzieści i pięć;
Jeriko jẹ́ ọ̀tàdínnírinwó ó lé márùn-ún
35 Synów Senaa trzy tysiące i sześć set i trzydzieści.
Senaa jẹ́ egbèji dín lógún ó lé ọgbọ̀n.
36 Kapłanów: Synów Jedajaszowych z domu Jesui, dziewięć set siedmdziesiąt i trzy;
Àwọn àlùfáà. Àwọn ọmọ Jedaiah (láti ipasẹ̀ ìdílé Jeṣua) jẹ́ ogún dín lẹ́gbẹ̀rin ó dín méje
37 Synów Immerowych tysiąc pięćdziesiąt i dwa;
Immeri jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀rún ó lé méjì
38 Synów Pashurowych tysiąc dwieście czterdzieści i siedm;
Paṣuri jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé mẹ́tàdínláàádọ́ta
39 Synów Harymowych tysiąc i siedmnaście.
Harimu jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó lé mẹ́tàdínlógún.
40 Lewitów: synów Jesui i Kadmiela, synów Hodawyjaszowych siedmdziesiąt i cztery.
Àwọn ọmọ Lefi. Àwọn ọmọ Jeṣua àti Kadmieli (ti ìdílé Hodafiah) jẹ́ mẹ́rìnléláàádọ́rin.
41 Śpiewaków: synów Asafowych sto dwadzieścia i ośm.
Àwọn akọrin. Àwọn ọmọ Asafu jẹ́ méjìdínláàádóje.
42 Synów odźwiernych: synów Sallumowych, synów Aterowych, synów Talmonowych, synów Akkubowych, synów Hatytowych, synów Sobajowych, wszystkich sto trzydzieści i dziewięć.
Àwọn aṣọ́bodè. Àwọn ará Ṣallumu, Ateri, Talmoni, Akkubu, Hatita àti Ṣobai jẹ́ mọ́kàndínlógóje.
43 Z Netynejczyków: synów Sycha, synów Chasufa, synów Tabbaota,
Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili. Àwọn ọmọ. Siha, Hasufa, Tabboati,
44 Synów Kierosa, synów Syaa, synów Fadona,
Kerosi, Siaha, Padoni,
45 Synów Lebana, synów Hagaba,
Lebana, Hagaba, Akkubu,
46 Synów Akkuba, synów Hagaba, synów Salmaja, synów Hanana,
Hagabu, Ṣalmai, Hanani,
47 Synów Gieddela, synów Gachera, synów Reajasza,
Giddeli, Gahari, Reaiah,
48 Synów Rezyna, synów Nekoda, synów Gazama,
Resini, Nekoda, Gassamu,
49 Synów Uzy, synów Fasejacha, synów Besaja,
Ussa, Pasea, Besai,
50 Synów Asena, synów Mehunima, synów Nefusyma;
Asna, Mehuni, Nefisimu,
51 Synów Bakbuka, synów Chakufa, synów Charchura,
Bakbu, Hakufa, Harhuri.
52 Synów Basluta, synów Mechyda, synów Charsa,
Basluti, Mehida, Harṣa,
53 Synów Barkosa, synów Sysera, synów Tamacha,
Barkosi, Sisera, Tema,
54 Synów Nezyjacha, synów Chatyfa,
Nesia àti Hatifa.
55 Synów sług Salomonowych, synów Sotaja, synów Sofereta, synów Peruda,
Àwọn ọmọ àwọn ìránṣẹ́ Solomoni. Àwọn ọmọ Sotai, Sofereti, Peruda,
56 Synów Jahala, synów Darkona, synów Giddela,
Jaala, Darkoni, Giddeli,
57 Synów Sefatyjasza, synów Chatyla, synów Pocheret Hasebaim, synów Ami;
Ṣefatia, àwọn ọmọ Hattili, Pokereti ti Haṣebaimu àti àwọn ọmọ Ami.
58 Wszystkich Netynejczyków, i synów sług Salomonowych trzy sta dziewięćdziesiąt i dwa.
Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti àwọn ọmọ àwọn ìránṣẹ́ Solomoni jẹ́ irinwó ó dín mẹ́jọ.
59 Ci też zasię wyszli z Telmelachu: Telcharsa, Cherub, Addam i Immer; ale nie mogli okazać domu ojców swoich, i nasienia swego, jeźli z Izraela byli.
Àwọn wọ̀nyí gòkè wá láti àwọn ìlú ti Teli-Mela, Teli-Harṣa, Kerubu, Addoni àti Immeri, ṣùgbọ́n wọn kò lè sọ pẹ̀lú ìdánilójú pé ìdílé àwọn wá láti ara ìran ẹ̀yà Israẹli.
60 Synów Delajaszowych, synów Tobijaszowych, synów Nekodowych, sześć set pięćdziesiąt i dwa.
Àwọn ọmọ Delaiah, Tobiah àti Nekoda jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀ta ó lé méjì.
61 A synów kapłańskich: synowie Habajowi, synowie Kozowi, synowie Barsylajego, który był pojął żonę z córek Barsylaja Galaadczyka; i nazwany był od imienia ich.
Àti nínú àwọn ọmọ àwọn àlùfáà. Àwọn ọmọ: Hobaiah, Hakosi àti Barsillai (ọkùnrin tí ó fẹ́ ọmọbìnrin Barsillai ará Gileadi a sì ń fi orúkọ náà pè é).
62 Ci szukali opisania rodu swego, ale nie znaleźli; przetoż zrzuceni są z kapłaństwa.
Àwọn wọ̀nyí wá ìwé ìrántí ìdílé wọn, ṣùgbọ́n wọn kò rí i, bẹ́ẹ̀ ni a kò kà wọ́n kún ara àlùfáà nítorí, a kà wọ́n sí aláìmọ́.
63 I zakazał im Tyrsata, aby nie jadali z rzeczy najświętszych, ażby powstał kapłan z Urym i z Tummim.
Baálẹ̀ pa á láṣẹ fún wọn pé wọn kò gbọdọ̀ jẹ nínú oúnjẹ mímọ́ jùlọ títí tí àlùfáà kan yóò fi ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú Urimu àti Tumimu.
64 Wszystkiego zgromadzenia było w jednym poczcie cztredzieści tysięcy dwa tysiące trzy sta i sześćdziesiąt;
Gbogbo ìjọ ènìyàn náà jẹ́ ẹgbàá mọ́kànlélógún ó lé òjìdínnírinwó.
65 Oprócz sług ich, i służebnic ich, których było siedm tysięcy trzy sta trzydzieści i siedm, a między nimi było śpiewaków i śpiewaczek dwieście.
Yàtọ̀ sí ẹgbẹ̀rin dín lẹ́gbàárin ó dín mẹ́tàlélọ́gọ́ta ìránṣẹ́ ọkùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin; wọ́n ní igba akọrin ọkùnrin àti obìnrin.
66 Koni ich siedm set trzydzieści i sześć; mułów ich dwieście czterdziści i pięć.
Wọ́n ní ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́rin ẹṣin; ìbáaka òjìlélúgba ó lé márùn-ún,
67 Wielbłądów ich cztery sta trzydzieści i pięć; osłów sześć tysięcy siedm set i dwadzieścia.
ràkunmí jẹ́ irinwó ó lé márùndínlógójì àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ẹgbẹ̀rin lé lọ́gbọ̀n ó dín ọgọ́rin.
68 A niektórzy z książąt domów ojcowskich przyszli do domu Pańskiego, który był w Jeruzalemie, ofiarowawszy się dobrowolnie, aby budowali dom Boży na miejscu jego.
Ní ìgbà tí wọ́n dé ilé Olúwa ní Jerusalẹmu, díẹ̀ nínú àwọn olórí àwọn ìdílé fi ọrẹ àtinúwá sílẹ̀ fún ṣíṣe àtúnkọ́ ilé Ọlọ́run ní ààyè rẹ̀.
69 Według przemożenia swego dali nakład na budowanie: złota łótów sześćdziesiąt tysięcy i jeden, a srebra grzywien pięć tysięcy, i szat kapłańskich sto.
Gẹ́gẹ́ bí agbára wọn, wọ́n fún ilé ìṣúra fún iṣẹ́ yìí ní ọ̀kẹ́ mẹ́ta ó lé lẹ́gbẹ̀rún ìwọ̀n dariki wúrà, ẹgbẹ̀rún márùn-ún fàdákà àti ọgọ́rùn-ún ẹ̀wù àlùfáà.
70 A tak osadzili się kapłani i Lewitowie, i niektórzy z ludu, i śpiewacy, i odźwierni, i Netynejczycy w miastach swych, i wszystek Izrael w miastach swych.
Àwọn àlùfáà, àwọn ará Lefi, àwọn akọrin, àwọn aṣọ́bodè àti àwọn ìránṣẹ́ ilé Olúwa ṣe àtìpó sínú àwọn ìlú wọn, pẹ̀lú àwọn ènìyàn mìíràn, àti ìyókù àwọn ọmọ Israẹli ṣe àtìpó sínú ìlú u wọn.

< Ezdrasza 2 >