< Kaznodziei 5 >

1 Strzeż nogi twojej, gdy idziesz do domu Bożego, a bądź skłonniejszym ku słuchaniu, niżeli ku dawaniu ofiar ludzi głupich; boć oni nie wiedzą, że źle czynią.
Ṣọ́ ìrìn rẹ nígbà tí o bá lọ sí ilé Ọlọ́run. Kí ìwọ kí ó sì múra láti gbọ́ ju àti ṣe ìrúbọ aṣiwèrè, tí kò mọ̀ wí pé òun ń ṣe búburú.
2 Nie bywaj porywczy do mówienia, ani serce twoje prędkie na wymówienie słowa przed obliczem Bożem, albowiem Bóg jest na niebie, a ty na ziemi; przeto niech słów twoich mało będzie.
Má ṣe yára pẹ̀lú ẹnu un rẹ, má sọ ohunkóhun níwájú Ọlọ́run. Ọlọ́run ń bẹ ní ọ̀run ìwọ sì wà ní ayé, nítorí náà jẹ́ kí ọ̀rọ̀ rẹ mọ ní ìwọ̀n.
3 Bo jako sen przychodzi z wielkiej pracy, tak głos głupiego z wielu słów.
Gẹ́gẹ́ bí àlá tí ń wá, nígbà tí ìlépa púpọ̀ wà, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rọ̀ òmùgọ̀ nígbà tí ọ̀rọ̀ bá pọ̀jù.
4 Gdy co Bogu poślubisz, nie omieszkiwaj tego oddać, boć mu się głupi nie podobają; cokolwiek poślubisz, oddaj.
Nígbà tí o bá ṣe ìlérí sí Ọlọ́run, má ṣe pẹ́ ní mímúṣẹ, kò ní inú dídùn sí òmùgọ̀, mú ìlérí rẹ sẹ.
5 Lepiej jest nie ślubować, niżeli poślubiwszy co, nie oddać.
Ó sàn láti má jẹ́ ẹ̀jẹ́, ju wí pé kí a jẹ́ ẹ̀jẹ́ kí a má mu ṣẹ lọ.
6 Nie dopuszczaj ustom twoim, aby do grzechu przywodziły ciało twoje, ani mów przed aniołem, że to jest błąd. Przeczże masz Boga gniewać mową swą, któryby wniwecz obrócił sprawę rąk twoich?
Má ṣe jẹ́ kí ẹnu rẹ tì ọ́ sínú ẹ̀ṣẹ̀. Má sì ṣe sọ fún òjíṣẹ́ ilé ìsìn pé, “Àṣìṣe ni ẹ̀jẹ́ mi.” Kí ló dé tí Ọlọ́run fi le è bínú sí ọ, kí ó sì ba iṣẹ́ ọwọ́ rẹ jẹ́?
7 Bo gdzie jest wiele snów, tam i marności i słów wiele; ale się ty Boga bój.
Asán ni ọ̀pọ̀ àlá àti ọ̀rọ̀ púpọ̀. Nítorí náà dúró nínú ìbẹ̀rù Ọlọ́run.
8 Jeźli ucisk ubogiego, i zatrzymanie sądu i sprawiedliwości ujrzysz w której krainie, nie dziwuj się temu; bo wyższy wysokiego upatruje, a jeszcze wyżsi są nad nimi.
Bí o bá rí tálákà tí wọ́n ń ni lára ní ojú púpọ̀, tí a sì ń fi òtítọ́ àti ẹ̀tọ́ rẹ̀ dù ú, má ṣe jẹ́ kí ó yà ọ́ lẹ́nu láti rí irú nǹkan bẹ́ẹ̀, nítorí pé ẹni tí ó wà ní ipò gíga máa ń mọ́ òṣìṣẹ́ tí ó wà lábẹ́ rẹ̀ lójú ni, síbẹ̀ àwọn kan sì wà tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn méjèèjì.
9 Zabawa koło ziemi ma pierwsze miejsce u wszystkich; i król roli służy.
Gbogbo wọn ni ó ń pín èrè tí wọ́n bá rí lórí ilẹ̀, àní ọba pàápàá ń jẹ èrè lórí oko.
10 Kto miłuje pieniądze, nie nasyci się pieniędzy, a kto miłuje bogactwa, nie będzie miał pożytku. I toć jest marność.
Ẹni tí ó bá ní ìfẹ́ owó kì í ní owó ànító, ẹni tí ó bá ní ìfẹ́ sí ọrọ̀ kì í ní ìtẹ́lọ́rùn pẹ̀lú èrè tí ó ń wọlé fún un.
11 Gdzie wiele majętności, wiele bywa tych, co ją jedzą. Cóż tedy za pożytek Panu z tego? jedno że na nie patrzy oczyma swemi.
Bí ẹrù bá ti ń pọ̀ sí i, náà ni àwọn tí ó ń jẹ ẹ́ yóò máa pọ̀ sí i Èrè e kí ni wọ́n sì jẹ́ sí ẹni tí ó ni nǹkan bí kò ṣe pé, kí ó máa mú inú ara rẹ dùn nípa rí rí wọn?
12 Słodki jest sen pracowitemu, chociaż mało, chociaż wiele jadł; ale nasycenie bogatego spać mu nie dopuści.
Oorun alágbàṣe a máa dùn, yálà ó jẹun kékeré ni tàbí ó jẹun púpọ̀, ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ ọlọ́rọ̀ kì í jẹ́ kí ó sùn rárá.
13 Jest ciężka bieda, którąm widział pod słońcem; bogactwa zachowane na złe pana swego.
Mo ti rí ohun tí ó burú gidigidi lábẹ́ oòrùn ọrọ̀ tí a kó pamọ́ fún ìparun ẹni tó ni nǹkan.
14 Bo takowe bogactwo złą sprawą giną, a syn, którego spłodzi, nie będzie miał nic w rękach swych.
Tàbí ọrọ̀ tí ó sọnù nípa àìrí ojúrere, nítorí wí pé bí ó bá ní ọmọkùnrin kò sí ohun tí yóò fi sílẹ̀ fún un.
15 Jako nagi wyszedł z żywota matki swojej, tak się wraca, jako był przyszedł, a nie odnosi nic z pracy swojej, coby miał wziąć w rękę swoję.
Ìhòhò ni ènìyàn wá láti inú ìyá rẹ̀, bí ó sì ṣe wá, bẹ́ẹ̀ ni yóò kúrò kò sí ohunkóhun nínú iṣẹ́ rẹ̀ tí ó le mú ní ọwọ́ rẹ̀.
16 A tak i toć jest ciężka bieda, że jako przyszedł, tak odejdzie. Cóż tedy za pożytek, że na wiatr pracował?
Ohun búburú gbá à ni eléyìí pàápàá. Bí ènìyàn ṣe wá, ni yóò lọ kí wá ni èrè tí ó jẹ nígbà tí ó ṣe wàhálà fún afẹ́fẹ́?
17 Dotego, że po wszystkie dni swoje w ciemności jadał z wielkim kłopotem, z boleścią i z gniewem.
Ó ń jẹ nínú òkùnkùn ní gbogbo ọjọ́ ọ rẹ̀, pẹ̀lú iyè ríra tí ó ga, ìnira àti ìbínú.
18 Toć jest, com ja obaczył, że dobra i osobliwa rzecz jest, jeść i pić, i używać dobrego ze wszystkiej pracy swej, którą człowiek podejmuje pod słońcem po wszystkie dni żywota swego, które mu dał Bóg; albowiem to jest dział jego.
Nígbà náà ni mo wá rí i dájú pé, ó dára, ó sì tọ̀nà fún ènìyàn láti jẹ, kí ó mu, kí ó sì ní ìtẹ́lọ́rùn nínú iṣẹ́ wàhálà rẹ̀ lábẹ́ oòrùn, ní àkókò ọjọ́ ayé díẹ̀ tí Ọlọ́run ti fi fún un, nítorí ìpín rẹ̀ ni èyí.
19 A któremukolwiek człowiekowi dał Bóg majętność i bogactwo, i dał mu w moc, aby ich używał, i odbierał dział swój, a weselił się z pracy swojej: to jest dar Boży.
Síwájú sí, nígbà tí Ọlọ́run fún ẹnikẹ́ni ní ọrọ̀ àti ohun ìní, tí ó sì fún un lágbára láti gbádùn wọn, láti gba ìpín rẹ̀ kí inú rẹ̀ sì dùn sí iṣẹ́ rẹ—ẹ̀bùn Ọlọ́run ni èyí.
20 Bo nie będzie wiele pamiętał na dni żywota swego; przeto, że mu Bóg życzy wesela serca jego.
Ó máa ń ronú lẹ́ẹ̀kọ̀ọ̀kan nípa ọjọ́ ayé rẹ lẹ́ẹ̀kọ̀ọ̀kan nítorí pé Ọlọ́run ń pa á mọ́ pẹ̀lú inú dídùn ní ọkàn rẹ̀.

< Kaznodziei 5 >