< Dagiti Salmo 64 >

1 O Dios, denggem ti timekko, denggem daytoy ararawko; annadam daytoy biagko iti panagbutengko kadagiti kabusorko.
Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Gbóhùn mi, Ọlọ́run, bí mo ti ń sọ àròyé mi pa ọkàn mi mọ́ kúrò lọ́wọ́ ẹ̀rù àwọn ọ̀tá.
2 Ilimmengnak iti nalimed a panagplano dagiti managdakdakes, manipud iti ringgor dagiti managbasol.
Pa mí mọ́ kúrò lọ́wọ́ ìmọ̀ ìkọ̀kọ̀ àwọn ènìyàn búburú kúrò nínú ọ̀pọ̀ igbe lọ́wọ́ ìrúkèrúdò oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀.
3 Pinatademda dagiti dilada a kasla kampilan; dagiti napapait a sasaoda, kasla pana nga imbiatda
Wọ́n pọ́n ahọ́n wọn bí idà, wọ́n sì fa ọrun wọn le láti tafà wọn, àní ọ̀rọ̀ kíkorò.
4 tapno mapanada ti awan basbasolna manipud iti nalimed a lugar; kellaat a panaenda isuna ket awan pagbutnganda.
Wọ́n tafà ní ìkọ̀kọ̀ sí àwọn aláìlẹ́ṣẹ̀: wọ́n tafà si lójijì, wọn kò sì bẹ̀rù.
5 Allukoyenda dagiti babbagida iti dakes a panggep; agtutulagda iti nalimed tapno mangisagana kadagiti palab-og; kunada, “Siasino ngay ti makakita kadatayo?”
Wọ́n, gba ara wọn níyànjú nínú èrò búburú, wọ́n sọ̀rọ̀ lórí dídẹkùn sílẹ̀ ní ìkọ̀kọ̀ wọ́n wí pé, “Ta ni yóò rí wa?”
6 Agaramidda kadagiti dakes a panggep; “Nalpastayon,” kunada, “ti naannad a plano.” Nauneg ti kaunggan a panunot ken puso ti tao.
Wọ́n gbìmọ̀ àìṣòdodo, wọ́n wí pé, “A wa ti parí èrò tí a gbà tán!” Lóòótọ́ àyà àti ọkàn ènìyàn kún fún àrékérekè.
7 Ngem panaen ida ti Dios; ket kellaat a masugatanda babaen kadagiti panana.
Ṣùgbọ́n Ọlọ́run yóò ta wọ́n ní ọfà; wọn ó sì gbọgbẹ́ lójijì.
8 Maitibkoldanto, agsipud ta maibusor kadakuada dagiti dilada; agwingiwingto amin dagiti makakita kadakuada.
Ahọ́n wọn yóò sì dojú ìjà kọ wọ́n, yóò sì run wọ́n, gbogbo ẹni tí ó bá rí wọn yóò sì mi orí fún wọn.
9 Agbutengto dagiti amin a tattao ket ipadamagdanto dagiti inaramid ti Dios. Sisisiribdanto a mangpanunot iti inaramidna.
Gbogbo ènìyàn yóò máa bẹ̀rù wọn ó kéde iṣẹ́ Ọlọ́run wọn ó dúró lé ohun tí ó ṣe.
10 Agragsakto dagiti nalinteg gapu iti inaramid ni Yahweh ken agkamangdanto kenkuana; amin dagiti naimbag, ipannakkeldanto isuna.
Jẹ́ kí olódodo kí ó yọ̀ nínú Olúwa yóò sì rí ààbò nínú rẹ̀. Gbogbo ẹni ìdúró ṣinṣin ní ọkàn yóò máa yìn ín.

< Dagiti Salmo 64 >