< II Na Lii 3 >

1 A LILO iho la o Iorama ke keiki a Ahaba i alii maluna o ka Iseraela ma Samaria, i ka makahiki he umi kumamawalu o Iehosapata, ke alii o ka Iuda, a he umikumamalua na makahiki ona i alii ai.
Jehoramu ọmọ Ahabu sì di ọba Israẹli ní Samaria ní ọdún kejìdínlógún ti Jehoṣafati ọba Juda, ó sì jẹ ọba fún ọdún méjìlá.
2 Hana ino aku la ia imua o Iehova, aole nae i like me ka kona makuakane a me ka kona makuwahine; no ka mea, lawe aku la ia i ke kii o Baala, ka mea a kona makuakane i hana'i.
Ó sì ṣe búburú níwájú Olúwa, ṣùgbọ́n kì í ṣe bí ti ìyá àti baba rẹ̀ ti ṣe. Ó gbé òkúta ère ti Baali tí baba rẹ̀ ti ṣe kúrò.
3 Aka, hoopili aku la ia i na hewa o Ieroboama ke keiki a Nebata, nana i hoolilo ka Iseraela i ka hewa; aole ia i haalele ia mau mea.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó fi ara mọ́ ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, tí ó ti fi Israẹli bú láti dẹ́ṣẹ̀; kò sì yí kúrò lọ́dọ̀ wọn.
4 A o Mesa ke alii o ka Moaba, he mea malama holoholona, a hookupu aku la ia no ke alii o ka Iseraela, i hookahi haneri tausani hipakeiki, a i hookahi haneri tausani hipakane me ka hulu.
Nísinsin yìí Meṣa ọba Moabu ń sin àgùntàn, ó sì gbọdọ̀ fi fún ọba Israẹli pẹ̀lú ọ̀kẹ́ márùn-ún ọ̀dọ́-àgùntàn àti pẹ̀lú irun ọ̀kẹ́ márùn-ún àgbò.
5 A i ka wa i make ai o Ahaba, kipi mai la ke alii o ka Moaba i ke alii o ka Iseraela.
Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ikú Ahabu, ọba Moabu ṣọ̀tẹ̀ lórí ọba Israẹli.
6 A hele aku la o Iorama ke alii mai Samaria aku, a helu aku i ka Iseraela a pau.
Lásìkò ìgbà yìí ọba Jehoramu jáde kúrò ní Samaria ó sì yí gbogbo Israẹli ní ipò padà.
7 Hele aku la ia, a hoouna aku io Iehosapata la ke alii o ka Iuda, i aku la, Ua kipi mai ke alii o ka Moaba ia'u: e hele pu anei oe me au e kaua aku i ka Moaba? I mai la ia, E hele no wau; ua like au me oe, ua like ko'u kanaka me kou kanaka, ua like ko'u mau lio me kou mau lio.
Ó sì ránṣẹ́ yìí sí Jehoṣafati ọba Juda pé, “Ọba Moabu sì ṣọ̀tẹ̀ sí mi. Ṣé ìwọ yóò lọ pẹ̀lú mi láti lọ bá Moabu jà?” Ọba Juda sì dáhùn pé, “Èmi yóò lọ pẹ̀lú rẹ. Èmi jẹ́ gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti wà, ènìyàn rẹ bí ènìyàn mi, ẹṣin mi bí ẹṣin rẹ.”
8 A ninau mai la ia, Ma ke ala hea kaua e pii aku ai? I aku la ia, Ma ke ala o ka waonahele o Edoma.
“Nípa ọ̀nà wo ni àwa yóò gbà dojúkọ wọ́n?” Ó béèrè. “Lọ́nà aginjù Edomu,” ó dáhùn.
9 A hele aku la ke alii o ka Iseraela, a me ke alii o ka Iuda, a me ke alii o ka Edoma; a hele poai lakou i ka hele ana i na la ehiku, aohe wai no ka poe kaua, a no na holoholona mahope o lakou.
Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli jáde lọ pẹ̀lú ọba Juda àti ọba Edomu. Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n yíká fún ọjọ́ méje. Àwọn ọmọ-ogun wọn kò ní omi púpọ̀ fún ara wọn tàbí fún ẹranko tí ó wà pẹ̀lú wọn.
10 I iho la ke alii o ka Iseraela, Auwe! no ka mea, ua hoakoakoa mai o Iehova i keia mau alii ekolu e hoolilo ia lakou iloko o ka lima o ka Moaba!
“Kí ni?” ọba Israẹli kígbe sókè. “Ṣé Olúwa pe àwa ọba mẹ́tẹ̀ẹ̀ta papọ̀ láti fi wá lé Moabu lọ́wọ́?”
11 I mai o Iehosapata, Aole anei he kaula a Iehova maanei, i ninau aku ai kakou ia Iehova ma ona la? Olelo aku la kekahi o na kauwa a ke alii o ka Iseraela, i aku la, Eia no o Elisai, ke keiki a Sapata, ka mea i ninini i ka wai maluna o na lima o Elia.
Ṣùgbọ́n Jehoṣafati sì wí pé, “Ṣé kò sí wòlíì Olúwa níbí, tí àwa ìbá ti ọ̀dọ̀ rẹ̀ béèrè lọ́wọ́ rẹ̀?” Ọ̀kan lára àwọn ìránṣẹ́ ọba Israẹli dáhùn pé, “Eliṣa ọmọ Ṣafati wà níbí. Ó máa sábà bu omi sí ọwọ́ Elijah.”
12 I mai la o Iehosapata, Ia ia no ka olelo a Iehova, A hele aku la ke alii o ka Iseraela, a me Iehosapata, a me ke alii o ka Edoma, io na la.
Jehoṣafati wí pé, “Ọ̀rọ̀ Olúwa wà pẹ̀lú rẹ̀.” Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli àti Jehoṣafati àti ọba Edomu sọ̀kalẹ̀ tọ̀ ọ́ lọ.
13 Ninau mai la o Elisai i ke alii o ka Iseraela, Heaha ka'u ia oe? e hele oe i na kaula a kou makuakane, a me na kaula a kou makuwahine. I aku la ke alii o ka Iseraela ia ia, Aole, no ka mea, ua hoakoakoa mai o Iehova i keia mau alii ekolu, e hoolilo ia lakou iloko o ka lima o ka Moaba.
Eliṣa wí fún ọba Israẹli pé, “Kí ni àwa ní ṣe pẹ̀lú ara wa? Lọ sọ́dọ̀ wòlíì baba rẹ àti wòlíì ti ìyá rẹ.” Ọba Israẹli dá a lóhùn, “Rárá, nítorí Olúwa ni ó pe àwa ọba mẹ́tẹ̀ẹ̀ta papọ̀ láti fi wá lé Moabu lọ́wọ́.”
14 I mai la o Elisai, Ma ke ola o Iehova o na kaua, imua ona a'u e ku nei, ina i manao ole au ia Iehosapata ke alii o ka Iuda, aole au e nana aku ia oe, aole hoi e ike ia oe.
Eliṣa wí pé, “Gẹ́gẹ́ bí ó ti wà pé Olúwa àwọn ọmọ-ogun wà láyé, ẹni tí mo ń sìn tí èmi kò bá ní ọ̀wọ̀ fún ojú Jehoṣafati ọba Juda, èmi kò ní wò ó tàbí èmi kì bá ti rí ọ.
15 E lawe mai i o'u nei i ka mea nana e hookani. A i kana hookani ana, maluna ona ka lima o Iehova.
Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, mú wá fún mi ohun èlò orin olókùn.” Nígbà tí akọrin náà n kọrin, ọwọ́ Olúwa wá sórí Eliṣa.
16 I mai la ia, Ke olelo mai nei o Iehova peneia, E hana i na luawai a paapu keia awawa.
Ó sì wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa sọ, ‘Jẹ́ kí àfonífojì kún fún ọ̀gbun.’
17 No ka mea, ke olelo mai nei o Iehova peneia, Aole oukou e ike i ka makani, aole hoi oukou e ike i ka ua; aka, e hoopihaia auanei keia awawa i ka wai i inu ai oukou, a me na bipi a oukou, a me na holoholona a oukou.
Nítorí èyí ni Olúwa wí, o kò ní í rí afẹ́fẹ́ tàbí òjò, bẹ́ẹ̀ ni àfonífojì yìí yóò kún pẹ̀lú omi, àti ìwọ àti ẹran ọ̀sìn àti pẹ̀lú àwọn ẹran yóò mu.
18 A he mea uuku keia i na maka o Iehova; e haawi no hoi ia i ka Moaba iloko o ko oukou lima.
Èyí jẹ́ ohun tí kò lágbára níwájú Olúwa, yóò sì fi Moabu lé e yín lọ́wọ́ pẹ̀lú.
19 A e luku aku oukou i na kulanakauhale a pau i paa i ka pa pohaku, a me na kulanakauhale maikai a pau, a e kua aku oukou i na laau maikai a pau, a e pani aku i na punawai a pau, e luku aku hoi i na kihapai maikai a pau i ka pohaku.
Ìwọ yóò sì bi gbogbo ìlú olódi àti gbogbo àgbà ìlú ṣubú. Ìwọ yóò sì gé gbogbo igi dáradára ṣubú, dá gbogbo orísun omi dúró, kí o sì pa gbogbo pápá dáradára pẹ̀lú òkúta run.”
20 A i kakahiaka, i ka manawa i kaumahaia'ku ai ka mohai ai, aia hoi, kahe mai la ka wai mai ka aoao o Edoma mai, a hoopihaia ka aina i ka wai.
Ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ní àsìkò ẹbọ, níbẹ̀ ni omí sàn láti ọ̀kánkán Edomu! Ilé náà sì kún pẹ̀lú omi.
21 A lohe ka Moaba a pau, ua hele mai na 'lii e kaua me lakou, hoakoakoa ae la lakou i na mea a pau e kaei ana i ke kaei kaua, a keu aku, a ku lakou ma ka mokuna.
Nísinsin yìí gbogbo ará Moabu gbọ́ pé àwọn ọba tí dé láti bá wọn jà. Bẹ́ẹ̀ ni gbogbo ènìyàn, ọmọdé àti àgbà tí ó lè ja ogun wọn pè wọ́n sókè wọ́n sì dúró ní etí ilẹ̀.
22 Ala ae la lakou i kakahiaka nui, a puka mai ka la maluna o ka wai, a ike aku la ka Moaba i ka wai mai o lakou aku, he ulaula e like me ke koko.
Nígbà tí wọ́n dìde ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, oòrùn ti tàn sí orí omi náà sí àwọn ará Moabu ní ìkọjá ọ̀nà, omi náà sì pupa bí ẹ̀jẹ̀.
23 I ae la lakou, He koko keia; ua lukuia na'lii, ua pepehi kekahi i kekahi; ina kakou i ka waiwai pio, e ka Moaba.
“Ẹ̀jẹ̀ ni èyí!” wọ́n wí pé, “Àwọn ọba wọ̀nyí lè ti jà kí wọn sì pa ara wọn ní ìpakúpa. Nísinsin yìí sí àwọn ìkógun Moabu!”
24 A hiki aku lakou i kahi hoomoana o ka Iseraela, ku mai la ka Iseraela, a pepehi mai la i ka Moaba, a hee aku la imua o lakou; a komo aku la lakou iloko, a pepehi aku la i ka Moaba.
Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn ará Moabu dé sí ibùdó ti Israẹli, àwọn ará Israẹli dìde, wọ́n sì kọlù wọ́n títí tí wọ́n fi sálọ. Àwọn ará Israẹli gbógun sí ilẹ̀ náà wọ́n sì pa Moabu run.
25 A wawahi aku la lakou i na kulanakauhale, a hoolei aku la kela kanaka keia kanaka i kona pohaku ma na kihapai maikai a pau a hoopiha iho la; a pani aku la lakou i na punawai a pau, a kua aku la i na laau maikai a pau, a koe aku la na pohaku iloko o Kireharaseta; aka, hoopuni aku la nae na mea maa, a luku aku la ia.
Wọ́n sì wọ gbogbo ìlú náà olúkúlùkù ènìyàn, wọ́n ju òkúta sí gbogbo ohun dáradára orí pápá títí tí ó fi run. Wọ́n sì dá gbogbo orísun omi dúró wọ́n sì gé gbogbo orísun dáradára. Kiri-Hareseti nìkan ni wọ́n fi òkúta rẹ̀ sílẹ̀ ní ààyè rẹ̀, ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn ológun pẹ̀lú kànnàkànnà yíká, wọ́n sì kọlù ìlú náà.
26 A ike aku la ke alii o ka Moaba, ua ikaika mai ke kaua ia ia, lawe aku la ia i ehiku haneri kanaka mea pahikaua, a hooikaika e hiki aku i ke alii o ka Edoma, aole nae lakou i hiki.
Nígbà tí ọba Moabu rí i wí pé ogun náà le ju ti òun lọ, ó mú idà pẹ̀lú ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin ọkùnrin onídà láti jà pẹ̀lú ọba Edomu, ṣùgbọ́n wọn kò yege.
27 Alaila lawe aku la ia i kana keiki hiapo, i ka mea nona ke aupuni mahope ona, a kaumaha aku ia ia i mohaikuni maluna o ka papohaku. A ua nui ka inaina i ka Iseraela; a haalele lakou ia ia, a hoi aku la i ka aina.
Nígbà náà ó mú àkọ́bí ọmọkùnrin rẹ̀, tí kò bá jẹ́ gẹ́gẹ́ bí ọba, ó sì fi rú ẹbọ sísun ní orí ògiri ìlú. Wọ́n sì bínú lórí Israẹli púpọ̀púpọ̀; wọ́n yọ́ kúrò wọ́n sì padà sí ìlú wọn.

< II Na Lii 3 >