< Psalms 136 >

1 O give thanks unto the LORD; for [he is] good: for his mercy [endureth] for ever.
Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí tí ó ṣeun;
2 O give thanks unto the God of gods: for his mercy [endureth] for ever.
Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run àwọn ọlọ́run:
3 O give thanks to the Lord of lords: for his mercy [endureth] for ever.
Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa àwọn olúwa,
4 To him who alone doeth great wonders: for his mercy [endureth] for ever.
Fún Òun nìkan tí ń ṣiṣẹ́ ìyanu ńlá;
5 To him that by wisdom made the heavens: for his mercy [endureth] for ever.
Fún ẹni tí ó fi ọgbọ́n dá ọ̀run;
6 To him that stretched out the earth above the waters: for his mercy [endureth] for ever.
Fún ẹni tí ó tẹ́ ilẹ̀ lórí omi;
7 To him that made great lights: for his mercy [endureth] for ever:
Fún ẹni tí ó dá àwọn ìmọ́lẹ̀ ńlá;
8 The sun to rule by day: for his mercy [endureth] for ever:
Òòrùn láti jẹ ọba ọ̀sán;
9 The moon and stars to rule by night: for his mercy [endureth] for ever.
Òṣùpá àti ìràwọ̀ láti jẹ ọba òru;
10 To him that smote Egypt in their firstborn: for his mercy [endureth] for ever:
Fún ẹni tí ó kọlu Ejibiti lára àwọn àkọ́bí wọn;
11 And brought out Israel from among them: for his mercy [endureth] for ever:
Ó sì mú Israẹli jáde kúrò láàrín wọn;
12 With a strong hand, and with a stretched out arm: for his mercy [endureth] for ever.
Pẹ̀lú ọwọ́ agbára àti apá nínà;
13 To him which divided the Red sea into parts: for his mercy [endureth] for ever:
Fún ẹni tí ó pín Òkun pupa ní ìyà;
14 And made Israel to pass through the midst of it: for his mercy [endureth] for ever:
Ó sì mú Israẹli kọjá láàrín rẹ̀
15 But overthrew Pharaoh and his host in the Red sea: for his mercy [endureth] for ever.
Ṣùgbọ́n ó bi Farao àti ogun rẹ̀ ṣubú nínú Òkun pupa;
16 To him which led his people through the wilderness: for his mercy [endureth] for ever.
Fún ẹni tí ó sin àwọn ènìyàn rẹ̀ la aginjù já
17 To him which smote great kings: for his mercy [endureth] for ever:
Fún ẹni tí ó kọlu àwọn ọba ńlá;
18 And slew famous kings: for his mercy [endureth] for ever:
Ó sì pa àwọn ọba olókìkí
19 Sihon king of the Amorites: for his mercy [endureth] for ever:
Sihoni, ọba àwọn ará Amori
20 And Og the king of Bashan: for his mercy [endureth] for ever:
Àti Ogu, ọba Baṣani;
21 And gave their land for an heritage: for his mercy [endureth] for ever:
Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní,
22 [Even] an heritage unto Israel his servant: for his mercy [endureth] for ever.
Ìní fún Israẹli, ìránṣẹ́ rẹ̀,
23 Who remembered us in our low estate: for his mercy [endureth] for ever:
Ẹni tí ó rántí wa ní ìwà ìrẹ̀lẹ̀ wa;
24 And hath redeemed us from our enemies: for his mercy [endureth] for ever.
Ó sì dá wa ní ìdè lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa;
25 Who giveth food to all flesh: for his mercy [endureth] for ever.
Ẹni tí ó fi oúnjẹ fún àwọn ẹ̀dá gbogbo
26 O give thanks unto the God of heaven: for his mercy [endureth] for ever.
Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run ọ̀run;

< Psalms 136 >