< 2 Manghai 8 >

1 Elisha loh a capa aka hing huta te a voek tih, “Thoo lamtah namah neh na imkhui te cet uh laeh. Na bakuep nah noek ah bakuep mai. BOEIPA loh khokha ham a khue dongah khohmuen ah he kum rhih khuiah pai pueng ni,” a ti nah.
Nísinsin yìí, Eliṣa wí fún obìnrin náà tí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin jí padà sáyé pé, “Jáde lọ pẹ̀lú ìdílé rẹ kí o sì lọ dúró fún ìgbà díẹ̀ ní ibikíbi tí o bá le dúró sí, nítorí Olúwa ti pàṣẹ ìyàn ní ìlú tí yóò lò tó ọdún méje.”
2 Te dongah huta te thoo tih Pathen hlang kah ol bangla a saii. Amah neh a imkhui te a caeh puei tih Philisti khohmuen ah kum rhih bakuep.
Obìnrin náà tẹ̀síwájú gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ ènìyàn Ọlọ́run ti sọ. Òun àti ìdílé rẹ̀ sí lọ, wọ́n sì ṣe àtìpó ní ilẹ̀ àwọn ará Filistini fún ọdún méje.
3 Kum rhih kah a bawtnah a pha vaengah tah huta te Philisti khohmuen lamloh mael. Te vaengah cet tih amah imkhui ham neh a khohmuen ham te manghai taengah pang.
Ní ẹ̀yìn ọdún méje ó sì padà wá láti ilẹ̀ àwọn ará Filistini ó sì lọ sí ọ̀dọ̀ ọba láti lọ bẹ̀ ẹ́ fún ilé àti ilẹ̀ rẹ̀.
4 Manghai loh Pathen hlang kah tueihyoeih Gehazi te a voek tih, “Elisha loh hno len cungkuem a saii te kai taengah tae laeh,” a ti nah.
Ọba sì ń sọ̀rọ̀ sí Gehasi, ìránṣẹ́ ènìyàn Ọlọ́run pé, “Sọ fún mi nípa gbogbo ohun ńlá tí Eliṣa ti ṣe.”
5 Te dongah aka duek tangtae a hing sak tih a capa koep aka hing huta loh a imkhui ham neh a khohmuen ham manghai taengah a pang te khaw manghai taengah a tae pah. Te phoeiah Gehazi loh, “Ka boei manghai aw, he huta he ni a capa Elisha loh a hing sak pah.
Bí Gehasi ti ń sọ bí tí Eliṣa ṣe jí òkú di alààyè, obìnrin náà tí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin tí Eliṣa ti dá padà sí ayé wá láti bẹ ọba fún ilé àti ilẹ̀ rẹ̀. Gehasi sì wí pé, “Obìnrin náà nìyìí olúwa mi ọba, ọmọkùnrin rẹ náà nìyí tí Eliṣa ti jí dìde sí ayé.”
6 Manghai loh huta te a dawt tih a taengah a tae pah vaengah tah manghai loh anih ham te imkhoem pakhat a khueh pah tih, “Khohmuen a hnoong khohnin lamloh tahae hil khohmuen kah a vueithaih cungkuem te anih taengah boeih mael laeh,” a ti nah.
Ọba béèrè lọ́wọ́ obìnrin náà nípa rẹ̀, ó sì sọ fún un. Ó sì yan ìjòyè kan fún ún fún ọ̀rọ̀ rẹ̀ ó sì wí fún un pé, “Ẹ fún un padà gbogbo ohun tí ó bá jẹ́ tirẹ̀, àti pẹ̀lú gbogbo èrè ilé rẹ̀ fún ún láti ọjọ́ tí ó ti kúrò ní ìlú títí di àsìkò yìí.”
7 Elisha te Damasku la a caeh vaengah Aram manghai Benhadad te ana tlo. Te dongah a taengla a puen pah tih, “Pathen kah hlang he la ha pawk,” a ti nah.
Eliṣa lọ sí Damasku, Beni-Hadadi ọba Siria ń ṣe àìsàn. Nígbà tí wọ́n sọ fún ọba pé, “Ènìyàn Ọlọ́run ti wá láti gbogbo ọ̀nà òkè síbí,”
8 Manghai loh Hazael te, “Na kut dongah khocang khuen lamtah Pathen kah hlang doe hamla cet laeh. Anih lamloh BOEIPA te dawt lah, he tloh lamloh ka hing venim?' dawt lah,” a ti nah.
ọba sì wí fún Hasaeli pé, “Mú ọrẹ lọ́wọ́ rẹ, sì lọ pàdé ènìyàn Ọlọ́run. Kí o sì béèrè Olúwa láti ọ̀dọ̀ rẹ̀, béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé ṣé èmi yóò sàn nínú àìsàn yìí?”
9 Te dongah anih doe hamla Hazael te cet tih a kut dongah khocang neh Damasku kah thennah cungkuem te kalauk sawmli phueih la a khuen. Cet tih a mikhmuh ah a pai vaengah tah, “Na capa Aram manghai Benhadad loh kai he nang taengla n'tueih, 'He tloh lamloh ka hing aya?' a ti,” a ti nah.
Hasaeli lọ láti pàdé Eliṣa, ó mú lọ pẹ̀lú rẹ̀ ẹ̀bùn gẹ́gẹ́ bí ogójì ẹrù ìbákasẹ tí gbogbo ìní tí ó dára jù fún wíwò ti Damasku, ó sì wọlé lọ ó sì dúró níwájú rẹ̀, ó sì wí pé, “Ọmọ rẹ Beni-Hadadi ọba Siria rán mi láti béèrè pé, ‘Ṣé èmi yóò sàn nínú àìsàn mi yìí?’”
10 Elisha loh anih te, “Cet lamtah amah taengah, 'Na hing rhoe na hing ni, 'ti nah. Tedae BOEIPA loh kai n'tueng coeng dongah duek rhoe duek ni,” a ti nah.
Eliṣa da á lóhùn pé, “Lọ kí o lọ sọ fún un pé, ‘Ìwo ìbá sàn nítòótọ́’; ṣùgbọ́n Olúwa ti fihàn mí pé nítòótọ́ òun yóò kùú.”
11 Te phoeiah tah a maelhmai te a khueh, a khueh tih a yah hil Pathen kah hlang te a rhah pah.
Ó sì ranjú mọ́ ọn pẹ̀lú àtẹjúmọ́ gidigidi títí tí ojú fi ti Hasaeli. Nígbà náà ènìyàn Ọlọ́run bẹ̀rẹ̀ sí ní sọkún.
12 Te vaengah Hazael loh, “Ka boeipa balae tih na rhah,” a ti nah hatah, “Israel ca rhoek taengah boethae na saii ham khaw, amih kah hmuencak te hmai neh na hlae ham khaw, amih kah tongpang rhoek te cunghang neh na ngawn ham khaw, amih kah camoe rhoek te na til ham khaw, aka vawn te na boe ham khaw ka ming dongah,” a ti nah.
“Kí ni ó dé tí olúwa mi fi ń sọkún?” Hasaeli béèrè. “Nítorí pé èmi mọ ibi tí ìwọ yóò ṣe sí Israẹli,” ó sì dáhùn pé, “Ìwọ yóò fi iná si odi agbára wọn, ìwọ yóò, pa àwọn ọ̀dọ́ ọmọkùnrin wọn pẹ̀lú idà, ìwọ yóò kọlù àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ wọn, ìwọ ó sì fọ́ wọn túútúú, ìwọ o sì la inú àwọn aboyún wọn.”
13 Tedae Hazael loh, “Na sal ui loh metlam hno len a saii eh?” a ti nah. Elisha loh, “Aram soah na manghai ham te BOEIPA loh kai n'tueng coeng,” a ti nah.
Hasaeli sì wí pé. “Báwo ni ìránṣẹ́ rẹ, ajá lásán làsàn yóò ṣe ṣe irú nǹkan ńlá bẹ́ẹ̀?” “Olúwa ti fihàn mí pé ìwọ ni yóò jẹ ọba Siria,” Eliṣa dá a lóhùn.
14 Elisha taeng lamloh nong tih a boei taengla a pawk vaengah anih te, “Elisha loh nang taengah balae a thui,” a ti nah. Te vaengah, “Kai taengah tah, ' Na hing rhoe na hing ni, ' a ti,” a ti nah.
Nígbà náà Hasaeli fi Eliṣa sílẹ̀ ó sì padà sí ọ̀dọ̀ ọ̀gá rẹ̀. Nígbà tí Beni-Hadadi béèrè, “Kí ni ohun tí Eliṣa sọ fún ọ?” Hasaeli dá a lóhùn, “Ó sọ fún mi wí pé ìwọ yóò sàn nítòótọ́.”
15 Tedae a vuen pha vaengah himbai thah a loh tih tui khuila a nuem phoeiah manghai kah maelhmai te a dah pah. Te vaengah manghai te duek tih Hazael te anih yueng la manghai.
Ṣùgbọ́n ní ọjọ́ kejì ó mú aṣọ tí ó nípọn, ó sì kì í bọ inú omi ó sì tẹ̀ ẹ́ sí ojú ọba, bẹ́ẹ̀ ni ó sì kú. Nígbà náà Hasaeli sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
16 Israel manghai Ahab capa Joram kah a kum nga dongkah, Judah manghai Jehoshaphat phoeiah tah, Judah manghai Jehoshaphat capa Jehoram te manghai.
Ní ọdún karùn-ún ti Joramu ọmọ Ahabu ọba Israẹli, nígbà tí Jehoṣafati jẹ́ ọba Juda, Jehoramu ọmọ Jehoṣafati bẹ̀rẹ̀ ìjọba rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba Juda.
17 Kum sawmthum kum nit a lo ca vaengah anih te manghai tih Jerusalem ah kum, kum rhet manghai.
Ó jẹ́ ẹni ọdún méjìlélọ́gbọ̀n nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́jọ.
18 Anih khaw Israel manghai rhoek kah longpuei ah pongpa. Ahab canu te anih yuu la a om dongah Ahab imkhui kah a saii bangla BOEIPA mikhmuh ah boethae a saii.
Ó sì rìn ní ọ̀nà ọba Israẹli, gẹ́gẹ́ bí ilé Ahabu ti lọ, nítorí ó fẹ́ ọmọbìnrin Ahabu ó sì ṣe ohun búburú níwájú Olúwa.
19 A sal David amah taengah a thui bangla anih ham neh a ca rhoek ham hnin takuem hmaithoi a khueh pah ham dongah ni BOEIPA loh Judah te phae a ngaih pawh.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, nítorí ti ìránṣẹ́ rẹ̀ Dafidi. Olúwa kò fẹ́ pa Juda run, ó ti ṣèlérí láti ṣètọ́jú ìmọ́lẹ̀ fún Dafidi àti àwọn ilé rẹ̀ títí láéláé.
20 Anih tue vaengah ni Edom loh Judah kut hmui lamkah boe a koek tih amamih ham manghai a manghai sak.
Ní àkókò Jehoramu, Edomu ṣọ̀tẹ̀ sí Juda, wọ́n sì gbé ọba tiwọn kalẹ̀.
21 Joram te amah taengkah leng boeih neh Zair te a paan. Khoyin ah thoo tih Edom te a tloek. A kaepvai te amah neh leng mangpa rhoek loh a dum vaengah pilnam tah amah dap la rhaelrham coeng.
Bẹ́ẹ̀ ni Jehoramu lọ sí Sairi pẹ̀lú gbogbo kẹ̀kẹ́ rẹ̀. Àwọn ará Edomu sì yí i ká àti kẹ̀kẹ́ àwọn olórí wọn, ṣùgbọ́n ó dìde dúró ní òru; àwọn ogun rẹ̀ síbẹ̀síbẹ̀, sá padà lọ ilé.
22 Edom tah tahae khohnin duela Judah kut hmui lamloh boe a koek. Libnah khaw te vaeng tue ah boe a koek coeng.
Títí ó fi di òní, Edomu wà nínú ọ̀tẹ̀ lórí Juda, Libina ṣọ̀tẹ̀ ní àkókò kan náà.
23 Joram kah ol noi neh a saii boeih te khaw Judah manghai rhoek kah khokhuen olka cabu dongah a daek uh moenih a?
Gẹ́gẹ́ bí fún iṣẹ́ mìíràn ti ìjọba Jehoramu, àti gbogbo ohun tí ó ṣe, ṣé a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda?
24 Joram te a napa rhoek taengla a khoem uh vaengah David khopuei ah a napa rhoek taengah a up. Te phoeiah a capa Ahaziah te anih yueng la manghai.
Jehoramu sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ a sì sin ín pẹ̀lú wọn ní ìlú Dafidi, Ahasiah ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
25 Israel manghai Ahab capa Joram kah kum hlai nit kum vaengah Judah manghai Jehoram capa Ahaziah te manghai van.
Ní ọdún méjìlá Joramu ọmọkùnrin Ahabu ọba Israẹli, Ahasiah ọmọkùnrin Jehoramu ọba Juda bẹ̀rẹ̀ ìjọba rẹ̀.
26 Ahaziah he kum kul kum nit a lo ca vaengah manghai tih Jerusalem ah kum khat manghai. A manu ming tah Israel manghai Omri canu Athaliah ni.
Ahasiah jẹ́ ẹni ọdún méjìlélógún nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní ọdún kan ní Jerusalẹmu. Orúkọ ìyá rẹ̀ a sì máa jẹ́ Ataliah, ọmọbìnrin Omri ọba Israẹli.
27 Anih he Ahab imkhui loh a cava nah dongah Ahab imkhui kah longpuei ah pongpa tih BOEIPA mikhmuh ah Ahab imkhui bangla boethae a saii.
Nígbà tí ó rin ọ̀nà ilé Ahabu ó sì ṣe búburú níwájú Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ilé Ahabu ti ṣe, nítorí ó tan nípa ìgbéyàwó sí ìdílé Ahabu.
28 Ahab capa Joram neh Ramothgilead kah Aram manghai Hazael te caem la a paan vaengah Arammi loh Joram te a ngawn.
Ahasiah sì lọ pẹ̀lú Joramu ọmọ Ahabu lọ sí ogun lórí Hasaeli ọba Aramu ní Ramoti Gileadi. Àwọn ará Siria ṣẹ́ Joramu lẹ́sẹ̀.
29 Te dongah manghai Joram khaw Aram manghai Hazael a vathoh thil vaengkah Ramah ah Arammi loh a ngawn. Te hmasoe te hoeih sak ham Jezreel la mael. Tedae anih te a nue coeng dongah Judah manghai Jehoram capa Ahaziah khaw Ahab capa Joram te sawt hamla Jezreel la suntla.
Bẹ́ẹ̀ ni ọba Joramu padà sí Jesreeli láti wo ọgbẹ́ rẹ̀ sàn tí ará Siria ti jẹ ní yà lórí rẹ̀ ní Ramoti ní ojú ogun rẹ̀ pẹ̀lú Hasaeli ọba Aramu. Nígbà náà Ahasiah ọmọ Jehoramu ọba Juda sọ̀kalẹ̀ lọ sí Jesreeli láti lọ wo Joramu ọmọ Ahabu nítorí tí ó fi ara pa.

< 2 Manghai 8 >