< اَلْمَزَامِيرُ 136 >
اِحْمَدُوا ٱلرَّبَّ لِأَنَّهُ صَالِحٌ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ١ 1 |
Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí tí ó ṣeun;
ٱحْمَدُوا إِلَهَ ٱلْآلِهَةِ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمتَهُ. | ٢ 2 |
Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run àwọn ọlọ́run:
ٱحْمَدُوا رَبَّ ٱلْأَرْبَابِ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ٣ 3 |
Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa àwọn olúwa,
ٱلصَّانِعَ ٱلْعَجَائِبَ ٱلْعِظَامَ وَحْدَهُ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ٤ 4 |
Fún Òun nìkan tí ń ṣiṣẹ́ ìyanu ńlá;
ٱلصَّانِعَ ٱلسَّمَاوَاتِ بِفَهْمٍ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ٥ 5 |
Fún ẹni tí ó fi ọgbọ́n dá ọ̀run;
ٱلْبَاسِطَ ٱلْأَرْضَ عَلَى ٱلْمِيَاهِ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ٦ 6 |
Fún ẹni tí ó tẹ́ ilẹ̀ lórí omi;
ٱلصَّانِعَ أَنْوَارًا عَظِيمَةً، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ٧ 7 |
Fún ẹni tí ó dá àwọn ìmọ́lẹ̀ ńlá;
ٱلشَّمْسَ لِحُكْمِ ٱلنَّهَارِ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ٨ 8 |
Òòrùn láti jẹ ọba ọ̀sán;
ٱلْقَمَرَ وَٱلْكَوَاكِبَ لِحُكْمِ ٱللَّيْلِ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ٩ 9 |
Òṣùpá àti ìràwọ̀ láti jẹ ọba òru;
ٱلَّذِي ضَرَبَ مِصْرَ مَعَ أَبْكَارِهَا، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ١٠ 10 |
Fún ẹni tí ó kọlu Ejibiti lára àwọn àkọ́bí wọn;
وَأَخْرَجَ إِسْرَائِيلَ مِنْ وَسَطِهِمْ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ١١ 11 |
Ó sì mú Israẹli jáde kúrò láàrín wọn;
بِيَدٍ شَدِيدَةٍ وَذِرَاعٍ مَمْدُودَةٍ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ١٢ 12 |
Pẹ̀lú ọwọ́ agbára àti apá nínà;
ٱلَّذِي شَقَّ بَحْرَ سُوفٍ إِلَى شُقَقٍ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ١٣ 13 |
Fún ẹni tí ó pín Òkun pupa ní ìyà;
وَعَبَّرَ إِسْرَائِيلَ فِي وَسَطِهِ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ١٤ 14 |
Ó sì mú Israẹli kọjá láàrín rẹ̀
وَدَفَعَ فِرْعَوْنَ وَقُوَّتَهُ فِي بَحْرِ سُوفٍ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ١٥ 15 |
Ṣùgbọ́n ó bi Farao àti ogun rẹ̀ ṣubú nínú Òkun pupa;
ٱلَّذِي سَارَ بِشَعْبِهِ فِي ٱلْبَرِّيَّةِ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ١٦ 16 |
Fún ẹni tí ó sin àwọn ènìyàn rẹ̀ la aginjù já
ٱلَّذِي ضَرَبَ مُلُوكًا عُظَمَاءَ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ١٧ 17 |
Fún ẹni tí ó kọlu àwọn ọba ńlá;
وَقَتَلَ مُلُوكًا أَعِزَّاءَ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ١٨ 18 |
Ó sì pa àwọn ọba olókìkí
سِيحُونَ مَلِكَ ٱلْأَمُورِيِّينَ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ١٩ 19 |
Sihoni, ọba àwọn ará Amori
وَعُوجَ مَلِكَ بَاشَانَ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ٢٠ 20 |
Àti Ogu, ọba Baṣani;
وَأَعْطَى أَرْضَهُمْ مِيرَاثًا، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ٢١ 21 |
Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní,
مِيرَاثًا لِإِسْرَائِيلَ عَبْدِهِ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ٢٢ 22 |
Ìní fún Israẹli, ìránṣẹ́ rẹ̀,
ٱلَّذِي فِي مَذَلَّتِنَا ذَكَرَنَا، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ٢٣ 23 |
Ẹni tí ó rántí wa ní ìwà ìrẹ̀lẹ̀ wa;
وَنَجَّانَا مِنْ أَعْدَائِنَا، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ٢٤ 24 |
Ó sì dá wa ní ìdè lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa;
ٱلَّذِي يُعْطِي خُبْزًا لِكُلِّ بَشَرٍ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ٢٥ 25 |
Ẹni tí ó fi oúnjẹ fún àwọn ẹ̀dá gbogbo
ٱحْمَدُوا إِلَهَ ٱلسَّمَاوَاتِ، لِأَنَّ إِلَى ٱلْأَبَدِ رَحْمَتَهُ. | ٢٦ 26 |
Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run ọ̀run;