< Numbers 7 >

1 Nígbà tí Mose ti parí gbígbé àgọ́ dúró, ó ta òróró sí i, ó sì yà á sí mímọ́ pẹ̀lú gbogbo àwọn ohun èlò rẹ̀, Ó tún ta òróró sí pẹpẹ, ó sì yà á sí mímọ́ pẹ̀lú gbogbo ohun èlò rẹ̀.
W dniu, w którym Mojżesz zakończył wznoszenie przybytku, namaścił go i poświęcił wraz ze wszystkimi jego sprzętami, a także ołtarz ze wszystkimi jego naczyniami, namaścił je i poświęcił.
2 Nígbà náà ni àwọn olórí Israẹli, àwọn ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan, àwọn alábojútó àwọn tí a kà náà mú ọrẹ wá.
Naczelnicy Izraela, głowy domów swoich ojców, którzy byli naczelnikami z [każdego] pokolenia i przełożonymi nad tymi, którzy zostali spisani, złożyli ofiary.
3 Wọ́n mú ọrẹ wọn wá síwájú Olúwa: kẹ̀kẹ́ ẹrù mẹ́fà ti abo, àti akọ màlúù kan láti ọ̀dọ̀ olórí kọ̀ọ̀kan àti kẹ̀kẹ́ ẹrù kan láti ọ̀dọ̀ olórí méjì. Wọ́n sì kó wọn wá sí iwájú àgọ́.
Przynieśli swoje ofiary przed PANA: sześć krytych wozów, dwanaście wołów, po jednym wozie na dwóch naczelników i po jednym wole na każdego, i przyprowadzili to przed przybytek.
4 Olúwa sọ fún Mose pé,
Wtedy PAN powiedział do Mojżesza:
5 “Gba gbogbo nǹkan wọ̀nyí lọ́wọ́ wọn, kí wọ́n ba à lè wúlò fún iṣẹ́ inú àgọ́ ìpàdé. Kó wọn fún àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ẹnìkọ̀ọ̀kan bá ṣe nílò rẹ̀.”
Weź to od nich na potrzebę służby w Namiocie Zgromadzenia i oddaj to Lewitom, każdemu według potrzeby jego służby.
6 Mose sì kó àwọn kẹ̀kẹ́ ẹrù àti akọ màlúù náà fún àwọn ọmọ Lefi.
Mojżesz wziął więc te wozy i woły i oddał je Lewitom.
7 Ó fún àwọn ọmọ Gerṣoni ní kẹ̀kẹ́ méjì àti akọ màlúù mẹ́rin, gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ wọn ṣe jẹ mọ́.
Dwa wozy i cztery woły dał synom Gerszona według potrzeby ich służby.
8 Ó fún àwọn ọmọ Merari ní kẹ̀kẹ́ mẹ́rin àti akọ màlúù mẹ́jọ gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ wọn ṣe jẹ mọ́. Gbogbo wọn wà lábẹ́ àkóso Itamari ọmọ Aaroni tí í ṣe àlùfáà.
Cztery zaś wozy i osiem wołów dał synom Merariego według potrzeby ich służby, pod nadzorem Itamara, syna kapłana Aarona.
9 Ṣùgbọ́n Mose kò fún àwọn ọmọ Kohati ní nǹkan kan nítorí pé èjìká wọn ni wọn yóò fi ru àwọn ohun mímọ́ èyí tí ó jẹ́ ojúṣe tiwọn.
Ale synom Kehata nie dał nic, bo ich służba w świątyni polegała na noszeniu na ramionach.
10 Nígbà tí a ta òróró sórí pẹpẹ. Àwọn olórí mú àwọn ọrẹ wọn wá fún ìyàsímímọ́ rẹ̀, wọ́n sì kó wọn wá síwájú pẹpẹ.
Naczelnicy ofiarowali swoje dary przed ołtarzem na jego poświęcenie, w tym dniu, w którym został namaszczony.
11 Nítorí tí Olúwa ti sọ fún Mose pé, “Olórí kọ̀ọ̀kan ní ọjọ́ kọ̀ọ̀kan ni yóò máa mú ọrẹ tirẹ̀ wá fún ìyàsímímọ́ pẹpẹ.”
I PAN powiedział do Mojżesza: Niech złożą swoje ofiary, inny naczelnik każdego dnia, na poświęcenie ołtarza.
12 Ẹni tí ó mú ọrẹ tirẹ̀ wá ní ọjọ́ kìn-ín-ní Nahiṣoni ọmọ Amminadabu láti inú ẹ̀yà Juda.
Pierwszego dnia swoją ofiarę złożył Nachszon, syn Amminadaba, z pokolenia Judy.
13 Ọrẹ rẹ̀ jẹ́: àwo fàdákà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò ti fàdákà tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ bí iye owó ibi mímọ́ àwo kọ̀ọ̀kan kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára tí a fi òróró pò gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun jíjẹ;
A jego ofiarę stanowiły: jedna srebrna misa wagi stu trzydziestu syklów, jedna srebrna czasza [wagi] siedemdziesięciu syklów według sykla świątynnego, obydwie pełne mąki pszennej zmieszanej z oliwą, na ofiarę pokarmową;
14 àwo wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá tí ó kún fún tùràrí;
Jedna czara z dziesięciu [syklów] złota pełna kadzidła;
15 ọ̀dọ́ akọ màlúù kan, àgbò kan, akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun,
Jeden młody cielec, jeden baran i jedno roczne jagnię na ofiarę całopalną;
16 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀,
Jeden kozioł z kóz na ofiarę za grzech;
17 akọ màlúù méjì, àgbò márùn-ún, òbúkọ ọlọ́dún kan márùn-ún tí wọn ó fi rú ẹbọ àlàáfíà. Wọ̀nyí ni ọrẹ Nahiṣoni ọmọ Amminadabu.
A na ofiarę pojednawczą – dwa woły, pięć baranów, pięć kozłów i pięć jednorocznych jagniąt. To była ofiara Nachszona, syna Amminadaba.
18 Ní ọjọ́ kejì ni Netaneli ọmọ Suari olórí àwọn ọmọ Isakari mú ọrẹ tirẹ̀ wá.
Drugiego dnia ofiarę złożył Netaneel, syn Suara, naczelnik [z pokolenia] Issachara.
19 Ọrẹ tí ó kó wá ní: àwo fàdákà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ bí iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀ọ̀kan sì kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára tí á fi òróró pò gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun jíjẹ;
Złożył on w ofierze jedną srebrną misę wagi stu trzydziestu syklów, jedną srebrną czaszę wagi siedemdziesięciu syklów według sykla świątynnego, obydwie pełne mąki pszennej zmieszanej z oliwą, na ofiarę pokarmową;
20 àwo wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá tí ó kún fún tùràrí,
Jedną czarę z dziesięciu [syklów] złota pełną kadzidła;
21 ọ̀dọ́ akọ màlúù kan, àgbò kan, àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan, fún ẹbọ sísun;
Jednego młodego cielca, jednego barana i jedno roczne jagnię na ofiarę całopalną;
22 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀;
Jednego kozła z kóz na ofiarę za grzech;
23 Màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún tí wọn ó fi rú ẹbọ àlàáfíà. Èyí ni ọrẹ Netaneli ọmọ Suari.
A na ofiarę pojednawczą – dwa woły, pięć baranów, pięć kozłów i pięć jednorocznych jagniąt. To [była] ofiara Netaneela, syna Suara.
24 Eliabu ọmọ Heloni, olórí àwọn ọmọ Sebuluni ni ó mú ọrẹ rẹ̀ wá ní ọjọ́ kẹta.
Trzeciego dnia [ofiarę złożył] naczelnik synów Zebulona Eliab, syn Chelona.
25 Àwọn ọrẹ rẹ̀ ni: àwo fàdákà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ bí iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀ọ̀kan sì kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára tí á fi òróró pò gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun jíjẹ;
Jego ofiarę stanowiły: jedna srebrna misa wagi stu trzydziestu [syklów], jedna srebrna czasza [wagi] siedemdziesięciu syklów według sykla świątynnego, obydwie pełne mąki pszennej zmieszanej z oliwą, na ofiarę pokarmową;
26 àwo wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá tí ó kún fún tùràrí;
Jedna czara z dziesięciu [syklów] złota pełna kadzidła;
27 akọ ọ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;
Jeden młody cielec, jeden baran i jedno roczne jagnię na ofiarę całopalną;
28 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀;
Jeden kozioł z kóz na ofiarę za grzech;
29 Màlúù méjì, àgbò márùn-ún, òbúkọ márùn-ún akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún tí wọn o fi rú ẹbọ àlàáfíà. Èyí ni ọrẹ Eliabu ọmọ Heloni.
A na ofiarę pojednawczą – dwa woły, pięć baranów, pięć kozłów i pięć jednorocznych jagniąt. To [była] ofiara Eliaba, syna Chelona.
30 Elisuri ọmọ Ṣedeuri olórí àwọn ọmọ Reubeni ni ó mú ọrẹ wá ní ọjọ́ kẹrin.
Czwartego dnia [ofiarę złożył] naczelnik synów Rubena Elizur, syn Szedeura.
31 Ọrẹ rẹ̀ ni: àwo fàdákà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ bí iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀ọ̀kan sì kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára tí á fi òróró pò gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun jíjẹ;
Jego ofiarę [stanowiły]: jedna srebrna misa wagi stu trzydziestu [syklów], jedna srebrna czasza [wagi] siedemdziesięciu syklów według sykla świątynnego, obydwie pełne mąki pszennej zmieszanej z oliwą, na ofiarę pokarmową;
32 àwo wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá tí ó kún fún tùràrí,
Jedna czara z dziesięciu syklów złota pełna kadzidła;
33 akọ ọ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;
Jeden młody cielec, jeden baran i jedno roczne jagnię na ofiarę całopalną;
34 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀;
Jeden kozioł z kóz na ofiarę za grzech;
35 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún tí wọn ó fi rú ẹbọ àlàáfíà. Èyí ni ọrẹ Elisuri ọmọ Ṣedeuri.
A na ofiarę pojednawczą – dwa woły, pięć baranów, pięć kozłów i pięć jednorocznych jagniąt. To była ofiara Elizura, syna Szedeura.
36 Ṣelumieli ọmọ Suriṣaddai, olórí àwọn ọmọ Simeoni ni ó mú ọrẹ wá ní ọjọ́ karùn-ún.
Piątego dnia [ofiarę złożył] naczelnik synów Symeona Szelumiel, syn Suriszaddaja.
37 Ọrẹ tí ó kó wá ni: àwo fàdákà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ bí iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀ọ̀kan sì kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára tí á fi òróró pò gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun jíjẹ;
Jego ofiarę stanowiły: jedna srebrna misa wagi stu trzydziestu [syklów], jedna srebrna czasza [wagi] siedemdziesięciu syklów według sykla świątynnego, obydwie pełne mąki pszennej zmieszanej z oliwą, na ofiarę pokarmową;
38 àwo wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá tí ó kún fún tùràrí;
Jedna czara z dziesięciu [syklów] złota pełna kadzidła;
39 akọ ọ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;
Jeden młody cielec, jeden baran i jedno roczne jagnię na ofiarę całopalną;
40 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀;
Jeden kozioł z kóz na ofiarę za grzech;
41 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún tí wọn ó fi rú ẹbọ àlàáfíà. Èyí ni ọrẹ Ṣelumieli ọmọ Suriṣaddai.
A na ofiarę pojednawczą – dwa woły, pięć baranów, pięć kozłów i pięć jednorocznych jagniąt. To [była] ofiara Szelumiela, syna Suriszaddaja.
42 Eliasafu ọmọ Deueli olórí àwọn ọmọ Gadi ní ó mú ọrẹ rẹ̀ wá ní ọjọ́ kẹfà.
Szóstego dnia [ofiarę złożył] naczelny synów Gada Eliasaf, syn Deuela.
43 Ọrẹ rẹ̀ ni: àwo fàdákà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ bí iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀ọ̀kan sì kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára tí á fi òróró pò gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun jíjẹ;
Jego ofiarę [stanowiły]: jedna srebrna misa wagi stu trzydziestu [syklów], jedna srebrna czasza [wagi] siedemdziesięciu syklów według sykla świątynnego, obydwie pełne mąki pszennej zmieszanej z oliwą, na ofiarę pokarmową;
44 àwo wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá tí ó kún fún tùràrí;
Jedna czara z dziesięciu [syklów] złota pełna kadzidła;
45 akọ ọ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;
Jeden młody cielec, jeden baran i jedno roczne jagnię na ofiarę całopalną;
46 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀;
Jeden kozioł z kóz na ofiarę za grzech;
47 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún, wọn ó fi rú ẹbọ àlàáfíà. Èyí ni ọrẹ Eliasafu ọmọ Deueli.
A na ofiarę pojednawczą – dwa woły, pięć baranów, pięć kozłów i pięć jednorocznych jagniąt. To była ofiara Eliasafa, syna Deuela.
48 Eliṣama ọmọ Ammihudu, olórí àwọn ọmọ Efraimu ni ó mú ọrẹ rẹ̀ wá ní ọjọ́ keje.
Siódmego dnia [ofiarę złożył] naczelnik synów Efraima Eliszama, syn Ammihuda.
49 Ọrẹ rẹ̀ ni: àwo fàdákà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ bí iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀ọ̀kan sì kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára tí á fi òróró pò gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun jíjẹ;
Jego ofiarę [stanowiły]: jedna srebrna misa wagi stu trzydziestu [syklów], jedna srebrna czasza [wagi] siedemdziesięciu syklów według sykla świątynnego, obydwie pełne mąki pszennej zmieszanej z oliwą, na ofiarę pokarmową;
50 àwo wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá tí ó kún fún tùràrí;
Jedna czara z dziesięciu [syklów] złota pełna kadzidła;
51 akọ ọ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;
Jeden młody cielec, jeden baran i jedno roczne jagnię na ofiarę całopalną;
52 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀;
Jeden kozioł z kóz na ofiarę za grzech;
53 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún, tí wọn ó fi rú ẹbọ àlàáfíà. Èyí ni ọrẹ Eliṣama ọmọ Ammihudu.
A na ofiarę pojednawczą – dwa woły, pięć baranów, pięć kozłów i pięć jednorocznych jagniąt. To [była] ofiara Eliszamy, syna Ammihuda.
54 Gamalieli ọmọ Pedasuri, olórí àwọn ọmọ Manase ni ó mú ọrẹ tirẹ̀ wá ní ọjọ́ kẹjọ.
Ósmego dnia [ofiarę złożył] naczelnik synów Manassesa Gamliel, syn Pedahsura.
55 Ọrẹ tirẹ̀ ni: àwo fàdákà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ bí iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀ọ̀kan sì kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára tí á fi òróró pò gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun jíjẹ;
Jego ofiarę [stanowiły]: jedna srebrna misa wagi stu trzydziestu [syklów], jedna srebrna czasza [wagi] siedemdziesięciu syklów według sykla świątynnego, obydwie pełne mąki pszennej zmieszanej z oliwą, na ofiarę pokarmową;
56 àwo wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá tí ó kún fún tùràrí;
Jedna czara z dziesięciu [syklów] złota pełna kadzidła;
57 akọ ọ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;
Jeden młody cielec, jeden baran i jedno roczne jagnię na ofiarę całopalną;
58 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀;
Jeden kozioł z kóz na ofiarę za grzech;
59 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún tí wọn ó fi rú ẹbọ àlàáfíà. Èyí ni ọrẹ Gamalieli ọmọ Pedasuri.
A na ofiarę pojednawczą – dwa woły, pięć baranów, pięć kozłów i pięć jednorocznych jagniąt. To była ofiara Gamliela, syna Pedahsura.
60 Abidani ọmọ Gideoni, olórí àwọn ọmọ Benjamini ni ó mú ọrẹ tirẹ̀ wá ní ọjọ́ kẹsànán.
Dziewiątego dnia [ofiarę złożył] naczelnik synów Beniamina Abidan, syn Gideoniego.
61 Ọrẹ rẹ̀ ni: àwo fàdákà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ bí iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀ọ̀kan sì kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára tí á fi òróró pò gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun jíjẹ;
Jego ofiarę [stanowiły]: jedna srebrna misa wagi stu trzydziestu [syklów], jedna srebrna czasza [wagi] siedemdziesięciu syklów według sykla świątynnego, obydwie pełne mąki pszennej zmieszanej z oliwą, na ofiarę pokarmową;
62 àwo wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá tí ó kún fún tùràrí;
Jedna czara z dziesięciu [syklów] złota pełna kadzidła;
63 akọ ọ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;
Jeden młody cielec, jeden baran i jedno roczne jagnię na ofiarę całopalną;
64 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀;
Jeden kozioł z kóz na ofiarę za grzech;
65 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún tí wọn ó fi rú ẹbọ àlàáfíà. Èyí ni ọrẹ Abidani ọmọ Gideoni.
A na ofiarę pojednawczą – dwa woły, pięć baranów, pięć kozłów i pięć jednorocznych jagniąt. To [była] ofiara Abidana, syna Gideoniego.
66 Ahieseri ọmọ Ammiṣaddai, olórí àwọn ọmọ Dani ni ó mú ọrẹ tirẹ̀ wá ní ọjọ́ kẹwàá.
Dziesiątego dnia [ofiarę złożył] naczelnik synów Dana Achiezer, syn Ammiszaddaja.
67 Ọrẹ rẹ̀ ni: àwo fàdákà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ bí iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀ọ̀kan sì kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára tí á fi òróró pò gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun jíjẹ;
Jego ofiarę [stanowiły]: jedna srebrna misa wagi stu trzydziestu [syklów], jedna srebrna czasza [wagi] siedemdziesięciu syklów według sykla świątynnego, obydwie pełne mąki pszennej zmieszanej z oliwą, na ofiarę pokarmową;
68 àwo wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá tí ó kún fún tùràrí;
Jedna czara z dziesięciu [syklów] złota pełna kadzidła;
69 akọ ọ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;
Jeden młody cielec, jeden baran i jedno roczne jagnię na ofiarę całopalną;
70 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀;
Jeden kozioł z kóz na ofiarę za grzech;
71 àti fún ẹbọ ti ẹbọ àlàáfíà, akọ màlúù méjì, àgbò márùn-ún, òbúkọ márùn-ún, akọ ọ̀dọ́-àgùntàn márùn-ún ọlọ́dún kan. Èyí ni ọrẹ ẹbọ tí Ahieseri ọmọ Ammiṣaddai.
A na ofiarę pojednawczą – dwa woły, pięć baranów, pięć kozłów i pięć jednorocznych jagniąt. To [była] ofiara Achiezera, syna Ammiszadaja.
72 Pagieli ọmọ Okanri, olórí àwọn ọmọ Aṣeri ni ó mú ọrẹ rẹ̀ wá ní ọjọ́ kọkànlá.
Jedenastego dnia [ofiarę złożył] naczelnik synów Aszera Pagiel, syn Okrana.
73 Ọrẹ rẹ̀ ni: àwo fàdákà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ bí iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀ọ̀kan sì kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára tí á fi òróró pò gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun jíjẹ;
Jego ofiarę [stanowiły]: jedna srebrna misa wagi stu trzydziestu [syklów], jedna srebrna czasza [wagi] siedemdziesięciu syklów według sykla świątynnego, obydwie pełne mąki pszennej zmieszanej z oliwą, na ofiarę pokarmową;
74 àwo wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá tí ó kún fún tùràrí;
Jedna czara z dziesięciu [syklów] złota pełna kadzidła;
75 akọ ọ̀dọ́ màlúù kan, àgbò kan àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;
Jeden młody cielec, jeden baran i jedno roczne jagnię na ofiarę całopalną;
76 akọ ewúrẹ́ fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀;
Jeden kozioł z kóz na ofiarę za grzech;
77 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún, tí wọn ó fi rú ẹbọ àlàáfíà. Èyí ni ọrẹ Pagieli ọmọ Okanri.
A na ofiarę pojednawczą – dwa woły, pięć baranów, pięć kozłów i pięć jednorocznych jagniąt. To [była] ofiara Pagiela, syna Okrana.
78 Ahira ọmọ Enani, olórí àwọn Naftali ni ó mú ọrẹ rẹ̀ wá ní ọjọ́ kejìlá.
Dwunastego dnia [ofiarę złożył] naczelnik synów Neftalego Achira, syn Enana.
79 Ọrẹ rẹ̀ ni: àwo fàdákà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádóje ṣékélì àti àwokòtò tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ àádọ́rin ṣékélì, méjèèjì gẹ́gẹ́ bí iye owó ibi mímọ́, àwo kọ̀ọ̀kan sì kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára tí á fi òróró pò gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun jíjẹ;
Jego ofiarę [stanowiły]: jedna srebrna misa wagi stu trzydziestu [syklów], jedna srebrna czasza [wagi] siedemdziesięciu syklów według sykla świątynnego, obydwie pełne mąki pszennej zmieszanej z oliwą, na ofiarę pokarmową;
80 àwo wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣékélì mẹ́wàá tí ó kún fún tùràrí;
Jedna czara z dziesięciu [syklów] złota pełna kadzidła;
81 akọ ọ̀dọ́ màlúù kan àgbò kan, àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun;
Jeden młody cielec, jeden baran i jedno roczne jagnię na ofiarę całopalną;
82 akọ ewúrẹ́ kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀;
Jeden kozioł z kóz na ofiarę za grzech;
83 màlúù méjì, àgbò márùn-ún, akọ ewúrẹ́ márùn-ún àti akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan márùn-ún, wọn ó fi rú ẹbọ àlàáfíà. Èyí ni ọrẹ Ahira ọmọ Enani.
A na ofiarę pojednawczą – dwa woły, pięć baranów, pięć kozłów i pięć jednorocznych jagniąt. To [była] ofiara Achiry, syna Enana.
84 Wọ̀nyí ni ọrẹ tí àwọn olórí àwọn ọmọ Israẹli mú wá fún ìyàsímímọ́ pẹpẹ nígbà tí wọ́n ta òróró sí i lórí: àwo fàdákà méjìlá, àwokòtò méjìlá, àwo wúrà méjìlá.
To było poświęcenie ołtarza, w tym dniu, w którym został namaszczony przez naczelników Izraela: dwanaście srebrnych mis, dwanaście srebrnych czasz, dwanaście złotych czar;
85 Àwo fàdákà kọ̀ọ̀kan wọn àádóje ṣékélì, àwokòtò kọ̀ọ̀kan sì wọn àádọ́rin. Àpapọ̀ gbogbo àwo fàdákà jẹ́ egbèjìlá ṣékélì gẹ́gẹ́ bí iye owó ibi mímọ́.
Każda srebrna misa [ważyła] sto trzydzieści [syklów], każda czasza – siedemdziesiąt [syklów]. Całego srebra w tych naczyniach było dwa tysiące czterysta syklów według sykla świątynnego;
86 Ọ̀kọ̀ọ̀kan àwo wúrà méjìlá tí tùràrí kún inú wọn ṣékélì mẹ́wàá mẹ́wàá gẹ́gẹ́ bí iye owó ibi mímọ́. Àpapọ̀ ìwọ̀n gbogbo àwo wúrà jẹ́ ọgọ́fà ṣékélì.
Złotych czar było dwanaście, pełnych kadzidła; każda [ważyła] dziesięć syklów według sykla świątynnego. Całego złota w tych czarach [było] sto dwadzieścia [syklów].
87 Àpapọ̀ iye ẹran fún ẹbọ sísun jẹ́ akọ ọ̀dọ́ màlúù méjìlá, àgbò méjìlá, akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan méjìlá pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ. Akọ ewúrẹ́ fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ jẹ́ méjìlá.
Wszystkich zwierząt na ofiarę całopalną było: dwanaście cielców, dwanaście baranów, dwanaście jednorocznych jagniąt wraz z ich ofiarą pokarmową i dwanaście kozłów z kóz na ofiarę za grzech.
88 Àpapọ̀ iye ẹran fún ọrẹ àlàáfíà jẹ́ màlúù mẹ́rìnlélógún, ọgọ́ta àgbò, ọgọ́ta akọ ewúrẹ́ àti ọgọ́ta akọ ọ̀dọ́ màlúù ọlọ́dún kan. Wọ̀nyí ni ọrẹ ìyàsímímọ́ pẹpẹ lẹ́yìn tí a ta òróró sí i.
A wszystkich zwierząt na ofiarę pojednawczą [było]: dwadzieścia cztery woły, sześćdziesiąt baranów, sześćdziesiąt kozłów i sześćdziesiąt jednorocznych jagniąt. To było poświęcenie ołtarza po jego namaszczeniu.
89 Nígbà tí Mose wọ inú àgọ́ ìpàdé láti bá Olúwa sọ̀rọ̀, Olúwa sì sọ̀rọ̀ sí i láti àárín àwọn kérúbù méjì láti orí ìtẹ́ àánú tí ó bo àpótí ẹ̀rí, ohùn náà sì bá Mose sọ̀rọ̀.
A gdy Mojżesz wchodził do Namiotu Zgromadzenia, aby rozmawiać z [Bogiem], wtedy słyszał głos mówiącego do niego z przebłagalni, która była nad arką świadectwa, spomiędzy dwóch cherubinów. I przemawiał do niego.

< Numbers 7 >