< Nehemiah 10 >

1 Àwọn tí ó fi èdìdì dì í ni: Nehemiah baálẹ̀, ọmọ Hakaliah. Sedekiah
Men de som beseglade det, voro desse: Nehemia Thirsatha, Hachalia son, och Zedekia,
2 Seraiah, Asariah, Jeremiah,
Seraja, Asaria, Jeremia,
3 Paṣuri, Amariah, Malkiah,
Pashur, Amaria, Malchija,
4 Hattusi, Ṣebaniah, Malluki,
Hattus, Sebanja, Malluch,
5 Harimu, Meremoti, Obadiah,
Harim, Meremoth, Obadja,
6 Daniẹli, Ginetoni, Baruku,
Daniel, Ginnethon, Baruch,
7 Meṣullamu, Abijah, Mijamini,
Mesullam, Abia, Mijamin,
8 Maasiah, Bilgai àti Ṣemaiah. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn àlùfáà.
Maasia, Bilgai, och Semaja: De voro Presterna.
9 Àwọn ọmọ Lefi: Jeṣua ọmọ Asaniah, Binnui ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Henadadi, Kadmieli,
Men Leviterna voro: Jesua, Asanja son, Binnui af Henadads barnom, Kadmiel;
10 àti àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ wọn: Ṣebaniah, Hodiah, Kelita, Pelaiah, Hanani,
Och deras bröder, Sebanja, Hodija, Kelita, Pelaja, Hanan,
11 Mika, Rehobu, Haṣabiah,
Micha, Rehop, Hasabia,
12 Sakkuri, Ṣerebiah, Ṣebaniah,
Saccur, Serebia, Sebanja,
13 Hodiah, Bani àti Beninu.
Hodija, Bani och Beninu.
14 Àwọn olórí àwọn ènìyàn: Paroṣi, Pahati-Moabu, Elamu, Sattu, Bani,
Hufvuden i folken voro: Paros, PahathMoab, Elam, Sattu, Bani,
15 Bunni, Asgadi, Bebai.
Bunni, Asgad, Bebai,
16 Adonijah, Bigfai, Adini,
Adonia, Bigvai, Adin,
17 Ateri, Hesekiah, Assuri,
Ater, Hiskia, Assur,
18 Hodiah, Haṣumu, Besai,
Hodija, Hasum, Bezai,
19 Harifu, Anatoti, Nebai,
Hariph, Anathoth, Nebai,
20 Magpiaṣi, Meṣullamu, Hesiri
Magpias, Mesullam, Hesir,
21 Meṣesabeli, Sadoku, Jaddua
Mesesabeel, Zadok, Jaddua,
22 Pelatiah, Hanani, Anaiah,
Pelatja, Hanan, Anaja,
23 Hosea, Hananiah, Haṣubu,
Hosea, Hanania, Hasub,
24 Halloheṣi, Pileha, Ṣobeki,
Hallohes, Pilha, Sobek,
25 Rehumu, Haṣabna, Maaseiah,
Rehum, Hasabna, Maaseja,
26 Ahijah, Hanani, Anani,
Ahija, Hanan, Anan,
27 Malluki, Harimu, àti Baanah.
Malluch, Harim och Baana.
28 “Àwọn ènìyàn tókù—àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi, àwọn aṣọ́nà, àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti gbogbo àwọn tí wọ́n ya ara wọn sọ́tọ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn àjèjì nítorí òfin Ọlọ́run, papọ̀ pẹ̀lú ìyàwó wọn, gbogbo ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wọn, tí òye yé
Och det andra folket, Presterna, Leviterna, dörravaktarena, sångarena, Nethinim, och alle de som hade söndrat sig ifrå folken i landen, intill Guds lag, med sina hustrur, söner och döttrar, alle de som det kunde förstå;
29 gbogbo wọn fi ara mọ́ àwọn arákùnrin wọn, àwọn ọlọ́lá, wọ́n sì fi ègún àti ìbúra dé ara wọn láti máa tẹ̀lé òfin Ọlọ́run tí a fi fún wọn ní ipasẹ̀ Mose ìránṣẹ́ Ọlọ́run àti láti pa gbogbo àṣẹ, ìlànà àti òfin Olúwa, wa mọ́ dáradára.
Och deras mägtige, togo sig det till för sina bröder, och de kommo till att svärja och förpligta sig med ed, till att vandra i Guds lag, som igenom Guds tjenare Mose gifven är, att de hålla och göra ville efter all Herrans vår Guds bud, rätter och seder;
30 “A ti ṣe ìlérí pé, a kò ní fi àwọn ọmọbìnrin wa fún àwọn tí wọ́n wà ní àyíká wa bí ìyàwó, tàbí fẹ́ àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin wa.
Och att vi icke skulle gifva folken i landena våra döttrar; ej heller vårom sönom taga deras döttrar.
31 “Nígbà tí àwọn ènìyàn àdúgbò bá mú ọjà tàbí oúnjẹ wá ní ọjọ́ ìsinmi láti tà, àwa kò ní rà á ní ọwọ́ wọn ní ọjọ́ ìsinmi tàbí ní ọjọ́ mímọ́ kankan. Ní gbogbo ọdún keje àwa kò ní ro ilẹ̀ náà, a ó sì pa gbogbo àwọn gbèsè rẹ́.
Desslikes, när folket i landet förer om Sabbathsdagen någon varo och allahanda spisning, till att sälja, att vi icke ville taga det af dem om Sabbathen och helgedagar; och att vi i sjunde årena ville göra förlösning på allahanda tunga;
32 “Àwa gbà ojúṣe láti máa pa àṣẹ mọ́ pé, a ó máa san ìdámẹ́ta ṣékélì ní ọdọọdún fún iṣẹ́ ilé Ọlọ́run wa:
Och lägga ett bud uppå oss, att vi årliga gifva skulle en tridiung af en sikel silfver, till tjensten i vår Guds hus;
33 nítorí oúnjẹ tí ó wà lórí tábìlì; nítorí ọrẹ ohun jíjẹ àti ẹbọ sísun ìgbà gbogbo; nítorí ọrẹ ọjọ́ ìsinmi, ti àyajọ́ oṣù tuntun àti àjọ̀dún tí a yàn; nítorí ọrẹ mímọ́; nítorí ọrẹ ẹ̀ṣẹ̀ láti ṣe ètùtù fún Israẹli; àti fún gbogbo iṣẹ́ ilé Ọlọ́run wa.
Nämliga till skådobröd, till dagligit spisoffer, till dagligit bränneoffer, på Sabbaths, nymånads och högtidsdagom, och till det helgada, och till syndoffer, der Israel skulle med försonad varda, och till all verk i vår Guds hus.
34 “Àwa, àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi àti àwọn ènìyàn náà ti dìbò láti pinnu ìgbà tí olúkúlùkù àwọn ìdílé yóò mú ọrẹ igi wá láti sun lọ́ríi pẹpẹ Olúwa Ọlọ́run wa sí ilé Ọlọ́run wa, ní àkókò tí a yàn ní ọdọọdún. Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ sínú ìwé òfin.
Och vi kastade lott emellan Presterna, Leviterna och folket, om vedoffer, det man till vår Guds hus årliga framföra skulle, efter våra fäders hus, på bestämd tid, att bränna på Herrans vår Guds altare, såsom det i lagen skrifvet är;
35 “Àwa tún gbà ojúṣe láti mú àkọ́so àwọn èso wa wá àti gbogbo èso igi wá ní ilé Olúwa.
Och till att årliga frambära förstlingen af vårt land, och förstlingen af allo frukt, af all trä till Herrans hus;
36 “Gẹ́gẹ́ bí a sì ti kọ ọ́ sínú ìwé òfin, àwa yóò mú àkọ́bí àwọn ọmọkùnrin wa, ti ohun ọ̀sìn wa, ti àwọn abo màlúù àti ti àwọn àgùntàn wa, wá sí ilé Ọlọ́run wa, fún àwọn àlùfáà tí ń ṣiṣẹ́ níbẹ̀.
Och förstlingen af våra söner, och af vår boskap, såsom det i lagen skrifvet står; och förstlingen af vårt fä, och af vår får, att vi allt detta skulle hafva in uti vår Guds hus till Presterna, som i vår Guds hus tjena;
37 “Síwájú sí i, àwa yóò mú àkọ́so oúnjẹ ilẹ̀ wa ti ọrẹ oúnjẹ, ti gbogbo èso àwọn igi àti ti wáìnì tuntun wa àti ti òróró wá sí yàrá ìkó nǹkan pamọ́ sí ilé Ọlọ́run wa àti fún àwọn àlùfáà. Àwa yóò sì mú ìdámẹ́wàá ohun ọ̀gbìn wá fún àwọn ọmọ Lefi, nítorí àwọn ọmọ Lefi ni ó ń gba ìdámẹ́wàá ní gbogbo àwọn ìlú tí a ti ń ṣiṣẹ́.
Och att vi ville frambära förstlingen af vår deg, och vårt häfoffer, och frukt af allahanda trä, vin och oljo, till Presterna, i kistorna vid vår Guds hus; och vårt lands tiond till Leviterna, så att Leviterna skulle hafva tionden i alla städer, der vårt åkerverk är.
38 Àlùfáà tí o ti ìdílé Aaroni wá ni yóò wá pẹ̀lú àwọn ọmọ Lefi nígbà tí wọ́n bá ń gba ìdámẹ́wàá, àwọn ọmọ Lefi yóò sì mú ìdámẹ́wàá ti ìdámẹ́wàá náà wá sí ilé Ọlọ́run, sí yàrá ìkó nǹkan pamọ́ sí inú ilé ìṣúra.
Och Presten Aarons son skall ock del hafva af Leviternas tiond, med Leviterna; så att Leviterna skola bära tionden af sine tiond upp till vår Guds hus, i kistorna, uti skatthuset.
39 Àwọn ènìyàn Israẹli, àti àwọn ọmọ Lefi gbọdọ̀ mú ọrẹ oúnjẹ, wáìnì tuntun àti òróró wá sí yàrá ìkó nǹkan pamọ́ sí níbi tí a pa ohun èlò ibi mímọ́ mọ́ sí àti ibi tí àwọn àlùfáà tí ń ṣe ìránṣẹ́ lọ́wọ́, àwọn aṣọ́nà àti àwọn akọrin máa ń dúró sí. “Àwa kì yóò gbàgbé tàbí ṣe àìbìkítà nípa ilé Ọlọ́run wa.”
Ty Israels barn, och Levi barn, skola bära häfoffret af säd, vin och oljo, upp i kistorna. Dersammastäds äro helgedomens kärile, och Presterna, som der tjena, och dörravaktare, och sångare; att vi vår Guds hus icke öfvergifve.

< Nehemiah 10 >