< Luke 20 >

1 Ní ọjọ́ kan, bí ó ti ń kọ́ àwọn ènìyàn ní tẹmpili tí ó sì ń wàásù ìyìnrere, àwọn olórí àlùfáà, àti àwọn akọ̀wé, pẹ̀lú àwọn àgbàgbà dìde sí i.
Ăn una zuvă kănd Isusu ănvăca ăn dvorištja alu Hramuluj š rubja alu lumjej Bună vorbă d Dimizov avinjit upruapje la jel glavni popurlje š učitelji d zakonu alu Mojsije š vođilje.
2 Wọ́n sì wí fún un pé, “Sọ fún wa, àṣẹ wo ni ìwọ fi ń ṣe nǹkan wọ̀nyí? Tàbí ta ni ó fún ọ ní àṣẹ yìí?”
Š jej la antribat: “Zi nuavă, dundjec pravo s fač aštja stvarurj? Činje ca dat vlast d asta?”
3 Ó sì dáhùn ó sì wí fún wọn pé, “Èmi pẹ̀lú yóò sì bi yín léèrè ọ̀rọ̀ kan; ẹ sì fi ìdáhùn fún mi.
A Isusu lja zăs alor: “Š jo osă ăntrijeb p voj. Zăčec mije
4 Ìtẹ̀bọmi Johanu, láti ọ̀run wá ni tàbí láti ọ̀dọ̀ ènìyàn?”
činje adat vlast alu Ivan karje bătjază s rubjaskă š s fakă aja ča fukut, Dimizov ili lumja?”
5 Wọ́n sì bá ara wọn gbèrò pé, “Bí àwa bá wí pé, ‘Láti ọ̀run wá ni,’ òun yóò wí pé, ‘Èéṣe tí ẹ̀yin kò fi gbà á gbọ́?’
Jej raspravlja ăntră jej če s zăkă alu Isusuluj. Jej azăs: “Akă zăčem: ‘Dimizov’, osă nji ăntrjabă: ‘Dăče atunča nu ja krizut?’
6 Ṣùgbọ́n bí àwa bá sì wí pé, ‘Láti ọ̀dọ̀ ènìyàn,’ gbogbo ènìyàn ni yóò sọ wá ní òkúta, nítorí wọ́n gbàgbọ́ pé, wòlíì ni Johanu.”
A akă zăčem: ‘Lumja’, tuată lumja osă arunče buluvanji š osă nji muară daja če je uvjeric k je Ivan proroku.”
7 Wọ́n sì dáhùn wí pé, “Àwa kò mọ̀ ibi tí ó ti wá.”
Atunča jej zăče alu Isusuluj k jej nu štije činje adat vlast alu Ivan.
8 Jesu sì wí fún wọn pé, “Ǹjẹ́ èmi kì yóò wí fún yín àṣẹ tí èmi fi ń ṣe nǹkan wọ̀nyí.”
A Isusu lja zăs: “Kum voj mije nu zăčec činje alu Ivan adat vlast, š jo nu zăk vuavă činje mije adat vlast!”
9 Nígbà náà ni ó bẹ̀rẹ̀ sí í pa òwe yìí fún àwọn ènìyàn pé, “Ọkùnrin kan gbin ọgbà àjàrà kan, ó sì fi ṣe àgbàtọ́jú fún àwọn olùṣọ́gbà, ó sì lọ sí àjò fún ìgbà pípẹ́.
Atunča Isusu lji spunje asta vorbă alu lumjej: “Njeki om asadit vinograd š adat ăn zajam alu omuluj karje lukrjază ku vinogradu. Atunča omula apljikat š na vinjit mult lunj.
10 Nígbà tí ó sì tó àkókò, ó rán ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ kan sí àwọn olùṣọ́gbà náà, kí wọn lè fún un nínú èso ọgbà àjàrà náà, ṣùgbọ́n àwọn alágbàtọ́jú lù ú, wọ́n sì rán an padà lọ́wọ́ òfo.
Kănd avinjit vrijamja d strugurj s lja dună, atrimjes gazda alu vinograduluj p argatu aluj s ja talu aluj d berbă. Ali lumja karje lukrjază ăn vinograd je la butut p argatu š la trimjes ăndrăt ku mănilje gualje.
11 Ó sì tún rán ọmọ ọ̀dọ̀ mìíràn, wọ́n sì lù ú pẹ̀lú, wọ́n sì jẹ ẹ́ ní yà, wọ́n sì rán an padà lọ́wọ́ òfo.
Atrimjes omu p altu argat, ali š p jel la butut š la dat d rušunje š la trimjes ăndrăt ku mănilje gualje.
12 Ó sì tún rán ẹ̀kẹta: wọ́n sì sá a lọ́gbẹ́ pẹ̀lú, wọ́n sì tì í jáde.
Gazda alu vinograduluj atrimjes aldă trje argat, ali jej p jel la ranit š la putirit.
13 “Nígbà náà ni Olúwa ọgbà àjàrà wí pé, ‘Èwo ni èmi ó ṣe? Èmi ó rán ọmọ mi àyànfẹ́ lọ: bóyá nígbà tí wọ́n bá rí i, wọn yóò bu ọlá fún un.’
Atunča gazda alu vinograduluj zăče: ‘Če s fakă? Osă trimjet p bijatu mjov karje jo vrjauv. Vjerovatno p jel osă l poštujaskă.’
14 “Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn alágbàtọ́jú náà rí i, wọ́n bá ara wọn gbèrò pé, ‘Èyí ni àrólé; ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a pa á, kí ogún rẹ̀ lè jẹ́ ti wa.’
Ali kănd lumja dăn vinograd avizut p bijatu, sa dogovorit š azăs: ‘Ăsta osă nasljedjaskă imanja. L umurăm š atunča imanja osă fije nostru!’
15 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì tì í jáde sẹ́yìn ọgbà àjàrà, wọ́n sì pa á. “Ǹjẹ́ kín ni olúwa ọgbà àjàrà náà yóò ṣe sí wọn?
La putirit dăn vinograd š la umurăt. Če găndic k osă fakă gazda alu vinograduluj kănd osă audă ča fost?
16 Yóò wá, yóò sì pa àwọn alágbàtọ́jú náà run, yóò sì fi ọgbà àjàrà náà fún àwọn ẹlòmíràn.” Nígbà tí wọ́n sì gbọ́, wọ́n ní, “Kí a má ri i!”
Osă vije š osă umuară p lumja dăn vinograd, a vinogradu osă dja ăn najam alu alcilor.” Lumja karje punje urjajke la Isusu, ja zăs: “Nikad nu fičem nješto aša rov!”
17 Nígbà tí ó sì wò wọ́n, ó ní, “Èwo ha ni èyí tí a ti kọ̀wé rẹ̀ pé: “‘Òkúta tí àwọn ọ̀mọ̀lé kọ̀sílẹ̀, òun náà ni ó di pàtàkì igun ilé’?
Atunča Isusu binje s ujtă p jej š zăče: “A če značaštje atunča aja čije skrisă ăn Svăntă pismă: ‘Buluvan karje graditelji arunkat postanit glavni buluvan alu zgradej’?
18 Ẹnikẹ́ni tí ó ṣubú lu òkúta náà yóò fọ́; ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tí òun bá ṣubú lù, yóò lọ̀ ọ́ lúúlúú.”
Toc karje kadje p buluvanula osă sparđje kašă găvanu d glină, š akă kadje ăla buluvanu p njeko osă fije măčinat.”
19 Àwọn olórí àlùfáà àti àwọn akọ̀wé ń wá ọ̀nà láti mú un ní wákàtí náà; ṣùgbọ́n wọ́n bẹ̀rù àwọn ènìyàn, nítorí tí wọ́n mọ̀ pé, ó pa òwe yìí mọ́ wọn.
Učitelji d zakonu alu Mojsije š glavni popurlje avrut odma s la puče p Isusu d aja k jej binje aštijut k Isusu rubjaštje aja vorbă d jej. Ali na fukut aja k lji irja frikă k lumja osă okrunjaskă păntruv jej.
20 Wọ́n sì ń ṣọ́ ọ, wọ́n sì rán àwọn ayọ́lẹ̀wò tí wọ́n ṣe ara wọn bí ẹni pé olóòtítọ́ ènìyàn, kí wọn ba à lè gbá ọ̀rọ̀ rẹ̀ mú, kí wọn ba à lè fi í lé agbára àti àṣẹ Baálẹ̀ lọ́wọ́.
Učitelji d zakon alu Mojsije š glavni popurlje la sljedit p Isusu š atrimjes dăpă jel špijunurj karje sa fukut k je iskreni. Avrut s apuče p Isusu k azăs nješto rov kum s l predajaskă alu upravitelj alu rimuluj ăn asta regija kum aputja s kaznjaskă p Isusu.
21 Wọ́n sì bí i, pé, “Olùkọ́ àwa mọ̀ pé, ìwọ a máa sọ̀rọ̀ fún ni, ìwọ a sì máa kọ́ni bí ó ti tọ́, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kì í ṣe ojúsàájú ẹnìkan ṣùgbọ́n ìwọ ń kọ́ni ní ọ̀nà Ọlọ́run lóòtítọ́.
Špijunurlje azăs alu Isusuluj, “Učiteljulje, štijem k rubješt š ănvăc istină š k nu ješt naklon alu unu om maj mult d altu, već ispravno ănvăc p lumja s trijaskă aša kum Dimizov vrja s jej trijaskă.
22 Ǹjẹ́ ó tọ́ fún wa láti máa san owó òde fún Kesari, tàbí kò tọ́?”
Spunje nuavă dali je dopustit s platim porezu alu caru alu Rimuluj ili nuje.”
23 Ṣùgbọ́n ó kíyèsi àrékérekè wọn, ó sì wí fún wọn pé,
Ali Isusu avizut k pokuša s l puče ăn zamkă š lja zăs:
24 “Ẹ fi owó idẹ kan hàn mí. Àwòrán àti àkọlé ti ta ni ó wà níbẹ̀?” Wọ́n sì dá a lóhùn pé, “Ti Kesari ni.”
“Rătăcăm kovanica d arđint ku karje s platjaštje porezu. Alu činje je slikaja š alu činje lumje p ja?” Jej aodgovorit: “Alu caruluj.”
25 Ó sì wí fún wọn pé, “Ǹjẹ́ ẹ fi ohun tí i ṣe ti Kesari fún Kesari, àti ohun tí í ṣe ti Ọlọ́run fún Ọlọ́run.”
Isusu lji zăča: “Atunča dăc alu caru čije alu caruluj, ali alu Dimizov dăc čije alu Dimizovuluj.”
26 Wọn kò sì lè gbá ọ̀rọ̀ rẹ̀ mú níwájú àwọn ènìyàn: ẹnu sì yà wọ́n sí ìdáhùn rẹ̀, wọ́n sì pa ẹnu wọn mọ́.
Daja na putut p Isusu pănglă toc s l optužaskă k azăs nješto če nuje binje, već atikut š sa mirat la vorbaja.
27 Àwọn Sadusi kan sì tọ̀ ọ́ wá, àwọn tí wọ́n ń wí pé àjíǹde òkú kò sí wọ́n sì bi í,
Atunča avinjit la Isusu njeki saduceji. Saduceji nu kridja k lumja s skuală dăla morc, daja jej azăs alu Isusu:
28 wí pé, “Olùkọ́, Mose kọ̀wé fún wa pé, Bí arákùnrin ẹnìkan bá kú, ní àìlọ́mọ, tí ó sì ní aya, kí arákùnrin rẹ̀ ṣú aya rẹ̀ lópó, kí ó lè gbé irú-ọmọ dìde fún arákùnrin rẹ̀.
“Učiteljulje, Mojsije askris ăn zakonu alu nostru k akă njeki om amurit š alăsat dăpă jel mujarja ali na vut kupi, fratilje aluj mora s ănsuarje p mujarja alu fratusov kum ja aputja s fakă bijat. Ăla bijat osă fije nasljedniku alu pămăntuluj alu omula karje amurit š s adukă lumje aluj.
29 Ǹjẹ́ àwọn arákùnrin méje kan ti wà; èkínní gbé ìyàwó, ó sì kú ní àìlọ́mọ.
Udată afost šaptje frac. Prvi fratje sa ănsurat š amurit frzdă kupi.
30 Èkejì sì ṣú u lópó: òun sì kú ní àìlọ́mọ.
Atunča altu fratje sa ănsurat ku mujarja alu fratusov karje amurit, ali š jel amurit.
31 Ẹ̀kẹta sì ṣú u lópó: gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn méjèèje pẹ̀lú: wọn kò sì fi ọmọ sílẹ̀, wọ́n sì kú.
Isto aša aldă trje fratje sa ănsurat š amurit. Š toc fracă karje arămas sa ănsurat ku ja š toc d šaptje frac amurit frzdă kupi.
32 Nígbẹ̀yìn pátápátá obìnrin náà kú pẹ̀lú.
Maj ănklo amurit š mujarja.
33 Ǹjẹ́ ní àjíǹde òkú, aya ti ta ni yóò ha ṣe nínú wọn? Nítorí àwọn méjèèje ni ó sá à ni í ní aya.”
Akă una zuvă toc morcă osă skualje, alu činje ja osă fije mujarja ăn zuvaja kănd irja mărtată dăpă toc šaptje frac?”
34 Jesu sì dáhùn ó wí fún wọn pé, “Àwọn ọmọ ayé yìí a máa gbéyàwó, wọn a sì máa fa ìyàwó fún ni. (aiōn g165)
Isusu lja zăs: “Lumja p pămăntusta s suară š s mărită. (aiōn g165)
35 Ṣùgbọ́n àwọn tí a kà yẹ láti jogún ìyè ayérayé náà, àti àjíǹde kúrò nínú òkú, wọn kì í gbéyàwó, wọn kì í sì í fa ìyàwó fún ni. (aiōn g165)
Ali lumja karje s skuală dăla morc trijaštje p pămăntu alu nov. Š p ălja karje Dimizov smatraštje k je dostojni s trijaskă p pămăntula, nusă ănsuară nič s miritje. (aiōn g165)
36 Nítorí wọn kò lè kú mọ́; nítorí tí wọn bá àwọn angẹli dọ́gba; àwọn ọmọ Ọlọ́run sì ni wọ́n, nítorí wọ́n di àwọn ọmọ àjíǹde.
Osă fije kašă anđeli daja če nikad nusă muară. Jej jaštje kupi alu Dimizov daja če Dimizov lja tors dăla morc.
37 Ní ti pé a ń jí àwọn òkú dìde, Mose tìkára rẹ̀ sì ti fihàn nínú igbó, nígbà tí ó pe ‘Olúwa ni Ọlọ́run Abrahamu, àti Ọlọ́run Isaaki, àti Ọlọ́run Jakọbu.’
Ali akuma, dal morcă osă skualje dăla muartje? Čak š Mojsije apokazăt k morcă osă skualje. Mojsije aja apokazăt ăn odlomaku d grmu karje ardje undje Mojsije azăs k Domnu jaštje ‘Dimizov alu Abraham š alu Izak š alu Jakov.’ A jej amurit mult aj majdată Mojsije azăs aja.
38 Bẹ́ẹ̀ ni òun kì í ṣe Ọlọ́run àwọn òkú, bí kò ṣe ti àwọn alààyè, nítorí gbogbo wọn wà láààyè fún un.”
A Dimizov nuje Dimizov alu ălja karje rămănje morc, već Dimizov alu lumje karje vije! Dimizov p tuată lumja smatrjaštje k jej vij.”
39 Nígbà náà ni àwọn kan nínú àwọn akọ̀wé dá a lóhùn, pé, “Olùkọ́ ìwọ wí rere!”
Atunča azăs njeki učitelji d zakonu alu Mojsije: “Učiteljulje, binje ajzăs!”
40 Wọn kò sì jẹ́ bi í léèrè ọ̀rọ̀ kan mọ́.
Dăpă aja nu sa osudit s ăntrijabă p Isusu aša pitanja.
41 Ó sì wí fún wọn pé, “Èéṣe tí wọ́n fi ń wí pé, ọmọ Dafidi ni Kristi?
Atunča Isusu lja tribat p lumja: “Dăče učitelji zăče k je Kristu bijatu alu Caru David?
42 Dafidi tìkára rẹ̀ sì wí nínú ìwé Saamu pé: “‘Olúwa sọ fún Olúwa mi pé: “Ìwọ jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún mi
K David săngur zăče ăn knjigă alu Psalam undje askris: ‘Domnu azăs alu Domnuluj alu mjov: Šăz p dirjaptă amja, s vladješt ku minje
43 títí èmi ó fi sọ àwọn ọ̀tá rẹ di àpótí ìtìsẹ̀ rẹ.”’
pănd nu puj p dušmanji alji tej kašă klupa dusu pičuarje alji tijalje.’
44 Ǹjẹ́ bí Dafidi bá pè é ní ‘Olúwa.’ Òun ha sì ti ṣe jẹ́ ọmọ rẹ̀?”
Jasno je k David p Mesija akimat ‘Domnu alu mjov’. Kum atunča Mesija puatje s fije samo potomaku alu David?”
45 Ó sì wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ní etí gbogbo ènìyàn pé,
Pănd narodu apus urjajke, Isusu azăs alu učenikurlje aluj:
46 “Ẹ máa kíyèsára lọ́dọ̀ àwọn akọ̀wé, tí wọ́n fẹ́ láti máa rìn nínú aṣọ gígùn, tí wọ́n sì fẹ́ ìkíni ní ọjà, àti ibùjókòó ọlá nínú Sinagọgu, àti ipò ọlá ní ibi àsè;
“Păzăcăvă d učitelji d zakonu alu Mojsije! Jej vrja s umblje okolo ku aljinilje alji marj š lumja s lji pozdravjaskă ku marje poštujală p ulic. Jej vrja s šagă p počasne lokurj ăn sinagogje š la nutje.
47 Àwọn tí ó jẹ ilé àwọn opó run, tí wọ́n sì ń gbàdúrà gígùn fún àṣehàn, àwọn wọ̀nyí náà ni yóò jẹ̀bi pọ̀jù.”
P prjevară ja imanja alu udovicilor, a s ruagă mult s puată lumja s lji vjadă. Jej osă fije kaznic maj rov d alcă lumje.”

< Luke 20 >