< Genesis 4 >

1 Adamu sì bá aya rẹ̀ Efa lòpọ̀, ó sì lóyún, ó sì bí Kaini. Ó wí pé, “Pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ Olúwa ni mo bí ọmọ ọkùnrin.”
Lao esa, Adam sungguꞌ no sao na Hawa, de ana nairu. Ana bꞌonggi ana touꞌ esa, ma nae, “Ana touꞌ esa dea nema ena, huu LAMATUALAIN tulu-fali au.” De babꞌae e, Kaen (sosoa na ‘dea nema’).
2 Lẹ́yìn náà, ó sì bí ọmọkùnrin mìíràn tí a pè ní Abeli. Abeli jẹ́ darandaran, Kaini sì jẹ́ àgbẹ̀.
Basa ma, Hawa bꞌonggi seluꞌ ana touꞌ esa, de babꞌae e Habel. Ruꞌa se raꞌamoko ma, Habel dadꞌi manatadꞌa banda, ma Kaen tao osi.
3 Ó sì ṣe lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, Kaini mú ọrẹ wá fún Olúwa nínú èso ilẹ̀ rẹ̀.
Lao esa, Kaen nendi osi na mbule-bꞌoa na ruma, fee LAMATUALAIN.
4 Ṣùgbọ́n Abeli mú ẹran tí ó sanra wá fún Olúwa nínú àkọ́bí ẹran ọ̀sìn rẹ̀. Olúwa sì fi ojúrere wo Abeli àti ọrẹ rẹ̀,
Habel o nendi bibꞌi lombo nara, ana ulu nara. Ana mbau-hala se, ma nendi sisi maloleꞌ neu Lamatualain. Ma LAMATUALAIN rala Na namahoꞌo, huu Habel, ma tutunu-hohotu na.
5 ṣùgbọ́n Olúwa kò fi ojúrere wo Kaini àti ẹbọ rẹ̀. Nítorí náà inú bí Kaini gidigidi, ojú rẹ̀ sì fàro.
Te Ana nda hii Kaen tutunu-hohotu na sa. Naa de, Kaen namanasa, de mata na maꞌalasi.
6 Nígbà náà ni Olúwa bi Kaini pé, “Èéṣe tí ìwọ ń bínú? Èéṣe tí ojú rẹ sì fàro?
Boe ma LAMATUALAIN olaꞌ no Kaen nae, “Heh, Kaen! Taꞌo bee de mumunasa, losa mata ma maꞌalasi taꞌo naa?
7 Bí ìwọ bá ṣe ohun tí ó tọ́, ṣé ìwọ kò ní jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà? Ṣùgbọ́n bí ìwọ kò bá ṣe ohun tí ó tọ́, ẹ̀ṣẹ̀ ń bẹ ní ẹnu-ọ̀nà rẹ, ó fẹ́ ní ọ ní ìní, ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ ṣe àkóso rẹ̀.”
Mete ma ho tao maloleꞌ, naa, Au simbo nggo no maloleꞌ boe. Te besa-bꞌesa! Mete ma ho tao deꞌulakaꞌ, dei fo deꞌulakaꞌ a naa baliꞌ nggo, onaꞌ meo obꞌo lafo. Dadꞌi mete ma hii mae tao deꞌulakaꞌ, malole lenaꞌ nggari hendi leo!”
8 Kaini wí fún Abeli arákùnrin rẹ̀ pé, “Jẹ́ kí a lọ sí oko.” Ó sì ṣe, bí wọ́n ti wà ní oko; Kaini da ojú ìjà kọ Abeli arákùnrin rẹ̀, ó sì pa á.
Lao esa, Kaen kokoe Habel nae, “Odꞌiꞌ! Uma fo teu lao-laoꞌ sia osi.” Ara losa naa, aiboiꞌ ma, Kaen momoko nisa odꞌi na.
9 Nígbà náà ni Olúwa béèrè lọ́wọ́ Kaini pé, “Níbo ni Abeli arákùnrin rẹ wà?” Ó sì dáhùn pé, “Èmi kò mọ ibi tí ó wà, èmí ha ń ṣe olùṣọ́ arákùnrin mi bí?”
Basa ma LAMATUALAIN natane Kaen nae, “Heh, Kaen! Odꞌi ma saa bee?” Nataa nae, “Au nda bubꞌuluꞌ saꞌ! Mae au mana toꞌu ei na, do?”
10 Olúwa wí pé, “Kín ni ohun tí ìwọ ṣe yìí? Gbọ́! Ẹ̀jẹ̀ arákùnrin rẹ ń kígbe pè mí láti ilẹ̀ wá.
Te Lamatualain olaꞌ nae, “Taꞌo bee de ho tao deꞌulaka taꞌo naa? Afiꞌ mae ho bisa funi odꞌi ma raa na sia rae a, te Au ita basa ena!
11 Láti ìsinsin yìí lọ, ìwọ ti wà lábẹ́ ègún, a sì ti lé ọ lórí ilẹ̀ tí ó ya ẹnu gba ẹ̀jẹ̀ arákùnrin rẹ lọ́wọ́ rẹ.
Ia naa huku-dokiꞌ sae nala nggo. Leleꞌ misa odꞌi ma, rae a musi nala raa na. De ia naa, rae a nda fee masodꞌaꞌ neu nggo sa ena.
12 Bí ìwọ bá ro ilẹ̀, ilẹ̀ kì yóò fi agbára rẹ̀ so èso rẹ̀ fún ọ mọ́. Ìwọ yóò sì jẹ́ ìsáǹsá àti alárìnkiri ni orí ilẹ̀ ayé.”
Mete ma ho tao osi, rae a nda fee mbule-bꞌoaꞌ saa-saa saꞌ boe. Mia oras ia, ho koo-kale muu-uma onaꞌ atahori mana toꞌa-taaꞌ sangga masodꞌaꞌ sia raefafoꞌ ia.”
13 Kaini wí fún Olúwa pé, “Ẹrù ìyà ẹ̀ṣẹ̀ mi pọ̀ ju èyí tí mo le rù lọ.
Te Kaen labꞌan LAMATUALAIN nae, “Awii! Lamatualain, e! Taꞌo bee de huku-doki au bera na seli, losa au nda lemba beꞌi sa!
14 Lónìí, ìwọ lé mi kúrò lórí ilẹ̀, mó sì di ẹni tí ó fi ara pamọ́ kúrò ní ojú rẹ, èmi yóò sì di ìsáǹsá àti alárìnkiri ní ayé, ẹnikẹ́ni tí ó bá rí mi, yóò sì pa mí.”
Huu Lamatualain oi hendi au sia mamanaꞌ ia, dei fo au uꞌudꞌoodꞌooꞌ mia Lamatualain. Au koo-kale sudꞌiꞌ a bee uu. Ma sudꞌiꞌ a se randaa ro au, naa, tati risa au.”
15 Ṣùgbọ́n, Olúwa wí fún pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́, bí ẹnikẹ́ni bá pa Kaini, èmi yóò gbẹ̀san ní ara onítọ̀hún ní ìgbà méje.” Nígbà náà ni Ọlọ́run fi àmì sí ara Kaini, kí ẹnikẹ́ni tí ó bá ri má ba à pa á.
Te LAMATUALAIN nataa nae, “Nda taꞌo naa sa! Seka tati nisa nggo, naa, Au huku-doki e bera na lenaꞌ lao hitu!” Dei de, LAMATUALAIN tao tatandaꞌ neu Kaen, fo atahori rahine, rae nda bole tao risa e sa.
16 Kaini sì kúrò níwájú Olúwa, ó sì ń gbé ilẹ̀ Nodi ní ìhà ìlà-oòrùn Edeni.
Basa ma, Kaen lao hela mamanaꞌ naa, fo neu naꞌadꞌodꞌoꞌ no LAMATUALAIN. Ana lao losa mamanaꞌ esa sia osi Eden seriꞌ rulu, nara na Nod, sosoa na nae, ‘koo-kale’. Boe ma, ana leo sia naa.
17 Kaini sì bá aya rẹ̀ lòpọ̀, ó sì lóyún, ó sì bí Enoku. Kaini sì tẹ ìlú kan dó, ó sì fi orúkọ ọmọ rẹ̀ ọkùnrin Enoku sọ ìlú náà.
Basa ma, Kaen sao, de sao na nairu. Ana bꞌonggi ana touꞌ esa, de babꞌae e, Henok. Kaen o nafefela kamboꞌ esa, de babꞌae kamboꞌ a Henok, tungga ana na nara na.
18 Enoku sì bí Iradi, Iradi sì ni baba Mehujaeli, Mehujaeli sì bí Metuṣaeli, Metuṣaeli sì ni baba Lameki.
Henok ana na, Irad. Ma Irad ana na, Mehuyael. Mehuyael ana na, Metusael. Ma Metusael ana na, Lamek.
19 Lameki sì fẹ́ aya méjì, orúkọ èkínní ni Adah, àti orúkọ èkejì ni Silla.
Lamek sao na rua. Esa naran Ada, ma esa naran Sila.
20 Adah sì bí Jabali, òun ni baba irú àwọn tí ń gbé inú àgọ́, tí wọ́n sì ń sin ẹran ọ̀sìn.
Ada ana ulu na, naran Yabal. Yabal tititi-nonosi nara, dadꞌi manatadꞌa. Ara rasodꞌa lali-laliꞌ, ma leo sia lalaat.
21 Orúkọ arákùnrin rẹ̀ ni Jubali, òun ni baba irú àwọn tí ń tẹ dùùrù tí wọ́n sì ń fọn fèrè.
Yabal odꞌi na, naran Yubal. Yubal tititi-nonosi nara, mana maꞌaminaꞌ lii-liiꞌ mana pake sanar onaꞌ a sasando, ma fuu onaꞌ suling.
22 Silla náà sì bí ọmọkùnrin tí ń jẹ́ Tubali-Kaini, tí ó ń rọ oríṣìíríṣìí ohun èlò láti ara idẹ àti irin. Arábìnrin Tubali-Kaini ni Naama.
Ma Lamek sao na Sila bꞌonggi Tubal Kaen. Tubal Kaen tititi-nonosi nara mana tutu besi. Ara tao sudꞌiꞌ a saa mataꞌ-mataꞌ mia besi ma riti. Tubal Kaen feto na, Naꞌama.
23 Lameki wí fún àwọn aya rẹ̀, “Adah àti Silla, ẹ tẹ́tí sí mi; ẹ̀yin aya Lameki, ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ mi. Mo ti pa ọkùnrin kan tí ó kọlù mí, ọ̀dọ́mọkùnrin tí ó pa mí lára.
Lao esa, Lamek nananaru ao na mia sao nara ruꞌa se mata nara nae, “Rena, e! Faꞌ ra monetenaꞌ esa tutu au, te au tao isa e.
24 Bí a ó bá gbẹ̀san Kaini ní ìgbà méje, ǹjẹ́ kí a gba ti Lameki nígbà mẹ́tàdínlọ́gọ́rin.”
Atahori mana tao nisa Kaen, hambu huku-dokiꞌ lao hitu. Te mete ma hambu mana nae nambedꞌaꞌ ralaꞌ no au, ana hambu huku-dokiꞌ lao hitu nulu hitu.”
25 Adamu sì tún bá aya rẹ̀ lòpọ̀, ó sì bí ọmọkùnrin kan tí ó pe orúkọ rẹ̀ ní Seti, tí ó túmọ̀ sí pé, “Ọlọ́run fún mi ní ọmọkùnrin mìíràn ní ipò Abeli tí Kaini pa.”
Adam sao na Hawa bonggi ana touꞌ esa fai. De ara babꞌae e, Set, huu Hawa nae, “Lamatualain fee anaꞌ ia nggati Habel, fo Kaen tao nisaꞌ a.”
26 Seti náà sì bí ọmọkùnrin kan, ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní Enoṣi. Láti àkókò náà lọ ni àwọn ènìyàn ti bẹ̀rẹ̀ sí ní ké pe orúkọ Olúwa.
Dꞌoo-dꞌoo ma, Set hambu ana touꞌ esa, naran Enos. Leleꞌ naa, atahori ra feꞌe rahine LAMATUALAIN ena, ma beꞌutee neu E.

< Genesis 4 >