< Genesis 14 >

1 Ní àsìkò yìí ni Amrafeli ọba Ṣinari, Arioku ọba Ellasari, Kedorlaomeri ọba Elamu àti Tidali ọba Goyimu
A kad bješe Amarfal car Senarski, Arioh car Elasarski, Hodologomor car Elamski i Targal car Gojimski,
2 jáde lọ láti bá Bera ọba Sodomu, Birṣa ọba Gomorra, Ṣenabu ọba Adma, Ṣemeberi ọba Seboimu àti ọba Bela (èyí ni Soari) jagun.
Zavojštiše na Valu cara Sodomskoga, i na Varsu cara Gomorskoga, i na Senara cara Adamskoga, i na Simovora cara Sevojimskoga i na cara od Valake, koja je sada Sigor.
3 Gbogbo àwọn ọba wọ̀nyí ni ó kó ogun wọn jọ pọ̀ sí àfonífojì Siddimu (ti o túmọ̀ sí Òkun Iyọ̀).
Svi se ovi skupiše u dolini Sidimskoj, koja je sada slano more.
4 Fún ọdún méjìlá gbáko ni wọ́n ti ń sin Kedorlaomeri bí ẹrú. Ṣùgbọ́n nígbà tí ó di ọdún kẹtàlá wọ́n ṣọ̀tẹ̀ sí i.
Dvanaest godina bjehu služili Hodologomoru, pa trinaeste godine odmetnuše se.
5 Ní ọdún kẹrìnlá, ni Kedorlaomeri àti àwọn ọba tí wọ́n ti jọ ni májẹ̀mú àṣepọ̀ wá, wọ́n ṣígun, wọ́n sì ṣẹ́gun ará Refaimu ní Aṣteroti-Karnaimu, àwọn ará Susimu ni Hamu, àwọn ará Emimu ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Kiriataimu,
A èetrnaeste godine doðe Hodologomor i carevi koji bijahu s njim, i pobiše Rafaje u Astarotu Karnajimskom i Zuzeje u Amu i Omeje u polju Kirijatajskom,
6 àti àwọn ará Hori ní orí òkè wọ̀n-ọn-nì Seiri, títí ó fi dé Eli-Parani ní etí ijù.
I Horeje u planini njihovoj Siru do ravnice Faranske pokraj pustinje.
7 Wọ́n sì tún yípadà lọ sí En-Miṣpati (ti o túmọ̀ sí Kadeṣi), wọ́n sì ṣẹ́gun gbogbo ilẹ̀ àwọn Amaleki, àti àwọn ará Amori tí ó tẹ̀dó sí Hasason Tamari pẹ̀lú.
Otuda vrativši se doðoše u En-Mispat, koji je sada Kadis, i isjekoše sve koji življahu u zemlji Amalièkoj, i Amoreje koji življahu u Asason-Tamaru.
8 Nígbà náà ni ọba Sodomu, ọba Gomorra, ọba Adma, ọba Seboimu àti ọba Bela (èyí ni Soari), kó àwọn ọmọ-ogun wọn, wọ́n sì pa ibùdó ogun wọn sí Àfonífojì Siddimu,
Tada izide car Sodomski i car Gomorski i car Adamski i car Sevojimski i car od Valake, koja je sada Sigor, izidoše na njih u dolinu Sidimsku,
9 láti kojú ìjà sí Kedorlaomeri ọba Elamu, Tidali ọba Goyimu, Amrafeli ọba Ṣinari àti Arioku ọba Ellasari (ọba mẹ́rin kọjú ìjà sí ọba márùn-ún).
Na Hodologomora cara Elamskoga, i na Targala cara Gojimskoga, i na Amarfala cara Senarskoga, i na Arioha cara Elasarskoga, èetiri cara na pet.
10 Àfonífojì Siddimu sì kún fún kòtò ọ̀dà ilẹ̀, nígbà tí ọba Sodomu àti ọba Gomorra sì sá, díẹ̀ nínú àwọn ọkùnrin ogun náà ṣubú sínú àwọn kòtò náà, àwọn tókù sì sálọ sì orí òkè.
A u dolini Sidimskoj bijaše mnogo rupa iz kojih se vadila smola; i pobježe car Sodomski i car Gomorski, i ondje padoše, a što osta pobježe u planinu.
11 Àwọn ọba mẹ́rẹ̀ẹ̀rin náà sì kó gbogbo ẹrù Sodomu àti Gomorra àti oúnjẹ wọn; wọ́n sì lọ.
I uzeše sve blago u Sodomu i Gomoru i svu hranu njihovu, i otidoše.
12 Wọ́n sì mú Lọti ọmọ arákùnrin Abramu tí ń gbé ní Sodomu àti gbogbo ohun ìní rẹ̀.
Uzeše i Lota, sinovca Avramova, i blago njegovo, i otidoše, jer življaše u Sodomu.
13 Ẹnìkan tí ó sá àsálà sì wá ròyìn fún Abramu, ará Heberu ni. Abramu sá ti tẹ̀dó sí ẹ̀gbẹ́ igi ńlá igbó Mamre ará Amori, arákùnrin Eṣkolu àti Aneri: àwọn ẹni tí ó ń bá Abramu ní àṣepọ̀.
A doðe jedan koji bješe utekao, te javi Avramu Jevrejinu, koji življaše u ravni Mamrija Amorejina, brata Esholu i brata Avnanu, koji bjehu u vjeri s Avramom.
14 Nígbà tí Abramu gbọ́ wí pé, a di Lọti ní ìgbèkùn, ó kó àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ tí a bí sí ilẹ̀ rẹ̀ tí ó sì ti kọ́ ni ogun jíjà jáde, wọ́n jẹ́ okòó lé lọ́ọ̀dúnrún ó dín méjì ènìyàn, ó sì lépa wọn títí dé Dani.
A kad Avram èu da mu se zarobio sinovac, naoruža sluge svoje, trista osamnaest, koji se rodiše u njegovoj kuæi, i poðe u potjeru do Dana.
15 Ní ọ̀gànjọ́ òru, Abramu pín àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ sí méjì, ó sì kọlù wọ́n, ó sì ṣẹ́gun wọn, ó sì lé wọn títí dé Hoba tí ó wà ní apá òsì Damasku.
Ondje razredivši svoje udari na njih noæu sa slugama svojim, i razbi ih, i otjera ih do Hovala, koji je na lijevo od Damaska,
16 Gbogbo ìkógun ni ó rí gbà padà àti ọmọ arákùnrin rẹ̀, Lọti pẹ̀lú ohun ìní rẹ̀, àti àwọn obìnrin pẹ̀lú àwọn ènìyàn tókù.
I povrati sve blago; povrati i Lota sinovca svojega s blagom njegovijem, i žene i ljude.
17 Nígbà tí Abramu ti ṣẹ́gun Kedorlaomeri àti àwọn ọba tí ó pẹ̀lú rẹ̀, ọba Sodomu lọ pàdé rẹ̀ ní àfonífojì Ṣafe (èyí ni àfonífojì Ọba).
A car Sodomski izide mu na susret kad se vrati razbivši Hodologomora i careve što bijahu s njim, u dolinu Savinu, koje je sada dolina careva.
18 Melkisedeki ọba Salẹmu sì mú oúnjẹ àti ọtí wáìnì jáde wá. Òun ni àlùfáà Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo.
A Melhisedek car Salimski iznese hljeb i vino; a on bijaše sveštenik Boga višnjega.
19 Ó sì súre fún Abramu, wí pé, “Ìbùkún ni fún Abramu ti Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo, Ẹni tí ó dá ọ̀run òun ayé.
I blagoslovi ga govoreæi: blagosloven da je Avram Bogu višnjemu, èije je nebo i zemlja!
20 Ìbùkún sì ni fún Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo jùlọ, tí ó fi àwọn ọ̀tá rẹ lé ọ lọ́wọ́.” Abramu sì fún un ní ìdámẹ́wàá ohun gbogbo.
I blagosloven da je Bog višnji, koji predade neprijatelje tvoje u ruke tvoje! I dade mu Avram desetak od svega.
21 Ọba Sodomu sì wí fún Abramu pé, “Kó àwọn ènìyàn mi fún mi, ṣùgbọ́n mú àwọn ẹrù fún ara rẹ.”
A car Sodomski reèe Avramu: daj meni ljude, a blago uzmi sebi.
22 Ṣùgbọ́n Abramu dá ọba Sodomu lóhùn pé, “Mo ti búra fún Olúwa, Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo, tí ó dá ọ̀run àti ayé, mo sì ti gbọ́wọ́ sókè,
A Avram reèe caru Sodomskom: dižem ruku svoju ka Gospodu Bogu višnjemu, èije je nebo i zemlja, zaklinjuæi se:
23 pé, èmi kì yóò mú láti fọ́nrán òwú títí dé okùn bàtà, àti pé, èmi kí yóò mú ohun kan tí ṣe tìrẹ, kí ìwọ kí ó má ba à wí pé, ‘Mo sọ Abramu di ọlọ́rọ̀.’
Ni konca ni remena od obuæe neæu uzeti od svega što je tvoje, da ne reèeš: ja sam obogatio Avrama;
24 Èmi kì yóò gba ohunkóhun yàtọ̀ sí ohun tí àwọn ọkùnrin mi ti jẹ́, ṣùgbọ́n fi ìpín fún àwọn ọkùnrin tí ó bá mi lọ, Aneri, Eṣkolu àti Mamre. Jẹ́ kí wọn kí ó gba ìpín wọn.”
Osim što su pojeli momci, i osim dijela ljudima koji su išli sa mnom, Esholu, Avnanu i Mamriju, oni neka uzmu svoj dio.

< Genesis 14 >