< Acts 15 >

1 Àwọn ọkùnrin kan tí Judea sọ̀kalẹ̀ wá, wọ́n sì kọ́ àwọn arákùnrin pé, “Bí kò ṣe pé a bá kọ yín ni ilà bí ìṣe Mose, ẹ̀yin kí yóò lè là.”
І, поприходивши деякі з Юдеї, навчали братів: що коли не обріжетесь по звичаю Мойсейовому, не можете спасти ся.
2 Nígbà tí Paulu àti Barnaba ni ìyapa àti ìyàn jíjà tí kò mọ níwọ̀n pẹ̀lú ara wọn, wọ́n yan Paulu àti Barnaba àti àwọn mìíràn nínú aposteli kí wọn gòkè lọ sí Jerusalẹmu, sọ́dọ̀ àwọn alàgbà nítorí ọ̀ràn yìí.
Як же почав ся спір і немале змаганнє Павла та Варнави з ними, то постановили, щоб Павел та Варнава і деякі инші з них пійшли до апостолів та старших у Єрусалим ради сього питання.
3 Nítorí náà, bí ìjọ ti rán wọn jáde lọ sí ọ̀nà wọn, wọn la Fonisia àti Samaria kọjá, wọ́n ń ròyìn ìyípadà àwọn aláìkọlà, wọ́n sì fi ayọ̀ ńlá fún gbogbo àwọn arákùnrin.
Вони ж, послані від церкви, проходили Финикию та Самарию, оповідуючи про наверненнє поган; і зробили великі радощі всїм братам.
4 Nígbà tí wọn sì dé Jerusalẹmu, ìjọ àti àwọn aposteli àti àwọn alàgbà tẹ́wọ́gbà wọ́n, wọ́n sì ròyìn ohun gbogbo tí Ọlọ́run ti ṣe nípasẹ̀ wọn.
Прийшовши ж у Єрусалим, прийняті були від церкви і апостолів і старших, і сповістили про все, що Бог з ними зробив.
5 Ṣùgbọ́n àwọn kan nínú ẹ̀yà àwọn Farisi tí wọ́n gbàgbọ́ dìde, wọ́n ń wí pé, “A ní láti kọ wọ́n ní ilà, àti láti pàṣẹ fún wọn pé kí wọn máa pa òfin Mose mọ́.”
Устали ж деякі з єресї Фарисейської, що увірували, кажучи, що треба обрізати їх та наказати, щоб хоронили закон Мойсеїв.
6 Àwọn aposteli àti àwọn alàgbà péjọ láti rí si ọ̀ràn yìí.
І зібрались апостоли та старші вглянути в сю річ.
7 Nígbà tí iyàn sì di púpọ̀, Peteru dìde, ó sì wí fún wọn pé, “Ará, ẹ̀yin mọ̀ pé, láti ìbẹ̀rẹ̀ ni Ọlọ́run ti yàn nínú yín pé, kí àwọn aláìkọlà lè gbọ́ ọ̀rọ̀ ìyìnrere láti ẹnu mi, kí wọn sì gbàgbọ́.
Як же постало велике змаганнє, вставши Петр, рече до них: Мужі брати, ви знаєте, що з давніх днїв Бог між нами вибрав мене, щоб через мої уста погане чули слово благовістя, та й увірували.
8 Ọlọ́run, tí ó jẹ́ olùmọ̀-ọkàn, sì jẹ́ wọn lẹ́rìí, ó fún wọn ni Ẹ̀mí Mímọ́, gẹ́gẹ́ bí àwa.
І Бог, що знав серця, сьвідкував їм, давши їм Духа сьвятого, як нам,
9 Kò sí fi ìyàtọ̀ sí àárín àwa àti àwọn, ó ń fi ìgbàgbọ́ wẹ̀ wọ́n lọ́kàn mọ́.
і не розріжнив нічого між нами й ними, вірою очистивши серця їх.
10 Ǹjẹ́ nítorí náà èéṣe tí ẹ̀yin o fi dán Ọlọ́run wò, láti fi àjàgà bọ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn lọ́rùn, èyí tí àwọn baba wa àti àwa kò lè rù?
Тепер же чого спокутуєте Бога, щоб наложив ярмо на шию ученикам, котрого нї батьки наші, ні ми не здолїли носити.
11 Ṣùgbọ́n àwa gbàgbọ́ pé nípa oore-ọ̀fẹ́ Olúwa Jesu àwa ó là, gẹ́gẹ́ bí àwọn.”
Нї віруємо, що благодаттю Господа Ісуса Христа спасемось, яко ж і вони.
12 Gbogbo àjọ sí dákẹ́, wọ́n sì fi etí sí Barnaba àti Paulu, tí wọn ń ròyìn iṣẹ́ ìyanu àti iṣẹ́ àmì tí Ọlọ́run tí ti ọwọ́ wọn ṣe láàrín àwọn aláìkọlà.
Умовкла ж уся громада, й слухала, як Варнава та Павел оповідували про ознаки та чудеса, що зробив Бог через них між поганами.
13 Lẹ́yìn tí wọn sì dákẹ́, Jakọbu dáhùn, wí pé, “Ará, ẹ gbọ́ tèmi,
Як же вмовкли вони, озвав ся Яков, говорячи: Мужі брати, вислухайте мене.
14 Simeoni ti ròyìn bí Ọlọ́run ti kọ́kọ́ bojú wo àwọn aláìkọlà, láti yàn ènìyàn nínú wọn fún orúkọ rẹ̀.
Симон оповів, як Бог перше зглянув ся, щоб з поган прийняти людей в імя своє.
15 Báyìí ni ọ̀rọ̀ àwọn wòlíì bá ṣe déédé; bí a ti kọ̀wé rẹ̀ pé:
З сим сходять ся слова пророчі, яко ж писано:
16 “‘Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí ni èmi ó padà, èmi ó sì tún àgọ́ Dafidi pa tí ó ti wó lulẹ̀: èmi ó sì tún ahoro rẹ̀ kọ́, èmi ó sì gbé e ró.
Після сього знов верну ся, і збудую намет Давидів, що впав, і руїни його збудую знов і поставлю його,
17 Kí àwọn ènìyàn ìyókù lè máa wá Olúwa, àti gbogbo àwọn kèfèrí, lára ẹni tí a ń pe orúkọ mi,’ ni Olúwa wí, ta ni ó ń ṣe nǹkan wọ̀nyí,
щоб остальні з людей шукали Господа, і всї народи, на котрих призвано імя моє, глаголе Господь, що робить оце все.
18 ẹni tí ó sọ gbogbo nǹkan wọ̀nyí di mímọ́ láti ọjọ́ pípẹ́ wá. (aiōn g165)
Звісні од віку Богові всі діла Його. (aiōn g165)
19 “Ǹjẹ́ ìmọ̀ràn tèmi ni pé, kí a máa ṣe yọ àwọn ti aláìkọlà ti ó yípadà sí Ọlọ́run lẹ́nu.
То ж суджу, що не треба тим докучати, которі від поган обернулись до Бога;
20 Ṣùgbọ́n kí a kọ̀wé si wọn, kí wọ́n fàsẹ́yìn kúrò nínú oúnjẹ tí a ṣe fún òrìṣà, àti kúrò nínú àgbèrè, àti nínú ẹ̀jẹ̀.
а написати їм, нехай удержують ся від ідолських гидот, та блуду, та давленого, та крови.
21 Nítorí òfin Mose nígbà àtijọ́ ṣá ní a ti ń wàásù rẹ̀, ni ìlú gbogbo, a máa ń kà á nínú Sinagọgu ni ọjọọjọ́ ìsinmi.”
Мойсей бо від стародавніх родів має проповідуючих його по городах, і читаний по школах що-суботи.
22 Nígbà nà án ni ó tọ́ lójú àwọn aposteli, àti àwọn alàgbà pẹ̀lú gbogbo ìjọ, láti yan ènìyàn nínú wọn, àti láti rán wọ́n lọ sí Antioku pẹ̀lú Paulu àti Barnaba: Judasi ti a ń pè àpèlé rẹ̀ ní Barsaba, àti Sila, ẹni tí ó lórúkọ nínú àwọn arákùnrin.
Зводили тодї апостоли і старші і вся церква вибраних мужів з між себе післати в Антиохию з Павлом та Варнавою: Юду, названого Варсавою, та Силу, мужів-проводирів мізк братами,
23 Wọn sì kọ ìwé lé wọn lọ́wọ́ báyìí pé, Àwọn aposteli, àti àwọn alàgbà, tí ó jẹ́ ti aláìkọlà tí ó wà ní Antioku, àti ní Siria, àti ní Kilikia.
написавши через руки їх так: Апостоли та старші і брати - братам з поган, що в Антиохиї, і Сириї і Киликиї, радуйте ся.
24 Níwọ́n bí àwa ti gbọ́ pé, àwọn kan ti ó ti ọ̀dọ̀ wa jáde wá ń fi ọ̀rọ̀ yọ yín lẹ́nu, tí wọ́n ń yí yín ní ọkàn padà (wí pé, ẹ kò gbọdọ̀ ṣàìmá kọ ilà, àti ṣàìmá pa òfin Mose mọ́), ẹni tí àwa kò fún ní àṣẹ.
Яко ж чули ми, що деякі з між нас вийшовши, потрівожили вас словами і захитали душі ваші, говорячи, щоб обрізувались та хоронили закон, чого ми їм не наказували;
25 Ó yẹ lójú àwa, bí wa ti fi ìmọ̀ ṣọ̀kan láti yan ènìyàn láti rán wọn sí yín, pẹ̀lú Barnaba àti Paulu àwọn olùfẹ́ wa.
то зводилось нам, зібравшим ся однодушне вибраних мужів післати до вас з любими нашими Варнавою та Павлом,
26 Àwọn ọkùnrin ti ó fi ọkàn wọn wéwu nítorí orúkọ Olúwa wa Jesu Kristi.
людьми, що віддавали душі свої за імя Господа нашого Ісуса Христа.
27 Nítorí náà àwa rán Judasi àti Sila àwọn tí yóò sì fi ọ̀rọ̀ ẹnu sọ ohun kan náà fún yín.
Післали ми оце Юду та Силу, котрі й самі розкажуть про те словом.
28 Nítorí ó dára lójú Ẹ̀mí Mímọ́, àti lójú wa, kí a má ṣe di ẹrù le é yin lórí, bí kò ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí tí ó ṣe pàtàkì;
Зводилось бо сьвятому Духу та й нам, ніякої тяготи більш не накладувати вам, опріч сього конечного:
29 í ẹ̀yin fàsẹ́yìn kúrò nínú ẹran ti à pa bọ òrìṣà, àti nínú ẹ̀jẹ̀ àti nínú ohun ìlọ́lọ́rùnpa, àti nínú àgbèrè. Bí ẹ̀yin bá pa ara yín mọ́ kúrò, ẹ̀yin ó ṣe rere. Àlàáfíà.
щоб удержувались від жертів ідолам, та крови, та давленого, та блуду. Від чого оберегаючи себе, добре робити мете. Бувайте здорові.
30 Ǹjẹ́ nígbà tí wọ́n sì fi wọ́n sílẹ̀ láti lọ, wọ́n sọ̀kalẹ̀ wá si Antioku. Nígbà tí wọn sì pé àwọn ìjọ papọ̀, wọn fi ìwé náà fún wọn.
Послані ж прийшли в Антиохию і, зібравши громаду, подали посланнє.
31 Nígbà tí wọn sì kà á, wọ́n yọ̀ fún ìtùnú náà.
Прочитавши ж (ті), зраділи від сього потїшення.
32 Bí Judasi àti Sila tìkára wọn ti jẹ́ wòlíì pẹ̀lú, wọ́n fi ọ̀rọ̀ púpọ̀ gba àwọn arákùnrin níyànjú, wọ́n sì mú wọn lọ́kàn le.
Юда ж та Сила, будучи самі пророками, многими словами втїшали братів і утверджували.
33 Nígbà tí wọn sì pẹ́, díẹ̀, àwọn arákùnrin rán wọn padà lọ ni àlàáfíà sí ọ̀dọ̀ àwọn tí ó rán wọn wá.
Пробувши ж (там якийсь) час, відпущені були з упокоєм од братів до апостолів.
Зводив же Сила зостатись там.
35 Paulu àti Barnaba sì dúró díẹ̀ ni Antioku, wọ́n ń kọ́ni, wọ́n sì ń wàásù ọ̀rọ̀, Olúwa, àti àwọn púpọ̀ mìíràn pẹ̀lú wọn.
Павел же та Варнава пробували в Антиохиї, навчаючи та благовіствуючи слово Господнє з многими иншими.
36 Lẹ́yìn ọjọ́ mélòó kan, Paulu sì sọ fún Barnaba pé, “Jẹ́ kí a tún padà lọ bẹ àwọn arákùnrin wa wò, bí wọn ti ń ṣe sí ni ìlú gbogbo tí àwa ti wàásù ọ̀rọ̀ Olúwa.”
По кількох же днях рече Павел до Варнави: Вернувшись одвідаємо братів наших по всіх городах, де проповідували ми слово Господнє, як вони мають ся.
37 Barnaba sì pinnu rẹ̀ láti mú Johanu lọ pẹ̀lú wọn, ẹni tí àpèlé rẹ̀ ń jẹ́ Marku.
Варнава ж раяв узяти з собою Йоана, званого Марком.
38 Ṣùgbọ́n Paulu rò pé, kò yẹ láti mú un lọ pẹ̀lú wọn, ẹni tí ó fi wọn sílẹ̀ ni Pamfilia, tí kò sì bá wọn lọ sí iṣẹ́ náà.
Павло ж не удостоїв брати з собою того, хто одлучивсь од них з Памфилиї, і не пійшов з ними на діло.
39 Ìjà náà sì pọ̀ tó bẹ́ẹ̀, tí wọn ya ara wọn sì méjì, Barnaba sì mu Marku ó tẹ ọkọ́ létí lọ sí Saipurọsi.
Постала ж ріжниця, так, що вони розлучились між собою; і Варнава, взявши Марка, поплив у Кипр,
40 Ṣùgbọ́n Paulu yan Sila, ó sì lọ, bí a ti fi lé oore-ọ̀fẹ́ Olúwa lọ́wọ́ láti ọ̀dọ̀ àwọn arákùnrin.
Павел же, вибравши Силу, пійшов, переданий благодатї Божій від братів,
41 Ó sì la Siria àti Kilikia lọ, ó ń mú ìjọ ní ọkàn le.
і проходив Сирию і Киликию, утверджаючи церкви.

< Acts 15 >