< 1 Chronicles 9 >

1 Gbogbo Israẹli ni a kọ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ àwọn baba ńlá nínú ìwé àwọn ọba Israẹli. Àwọn ènìyàn Juda ni a kó ní ìgbèkùn lọ sí Babeli nítorí àìṣòótọ́ wọn.
A tak wszyscy Izraelczycy obliczeni są; a oto zapisani są w księgach królów Izraelskich i Judzkich, a przeniesieni są do Babilonu dla przestępstwa swego.
2 Nísinsin yìí, àwọn tí ó kọ́kọ́ tún tẹ̀dó lórí ohun ìní wọn ní ìlú wọn ni díẹ̀ nínú àwọn ọmọ Israẹli, àwọn àlùfáà, àwọn ará Lefi àti àwọn ìránṣẹ́ ilé Olúwa.
Lecz którzy pierwsi mieszkali w osiadłościach swych i w miastach swoich, Izraelczycy, kapłani, Lewitowie, i Netynejczycy.
3 Àwọn tí ó wá láti Juda láti Benjamini àti láti Efraimu àti Manase tí ó ń gbé ní Jerusalẹmu jẹ́:
W Jeruzalemie mieszkali z synów Judowych, i z synów Benjaminowych, i z synów Efraimowych, i Manasesowych;
4 Uttai ọmọ Ammihudu, ọmọ Omri, ọmọ Imri, ọmọ Bani, ìran ọmọ Peresi ọmọ Juda.
Uttaj, syn Ammiuda, syna Amry, syna Imry, syna Bonny, z synów Faresa, syna Judowego.
5 Àti nínú ará Ṣilo: Asaiah àkọ́bí àti àwọn ọmọ rẹ̀.
A z Sylona: Asajasz pierworodny, i synowie jego.
6 Ní ti ará Sera: Jeueli. Àwọn ènìyàn láti Juda sì jẹ́ ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́wàá.
A z synów Zerachowych: Jehuel i braci ich sześć set i dziewięćdziesiąt.
7 Àti nínú àwọn ọmọ Benjamini ni: Sallu ọmọ Meṣullamu, ọmọ Hodafiah; ọmọ Hasenuah;
A z synów Benjaminowych: Salu, syn Mesullama, syna Hodowiego, syna Asenuowego.
8 Ibinaiah ọmọ Jerohamu; Ela ọmọ Ussi, ọmọ Mikri; àti Meṣullamu ọmọ Ṣefatia; ọmọ Reueli, ọmọ Ibinijah.
A Ibnijasz, syn Jerochamowy, i Ela, syn Uzego, syna Michry, i Mesullam, syn Sefatyjasza, syna Rehuelowego, syna Ibnijaszowego.
9 Àwọn ènìyàn láti Benjamini gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe kọ ọ́ nínú ìran wọn nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó dín mẹ́rìnlélógójì. Gbogbo àwọn ọkùnrin yí jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé.
Także braci ich według narodów ich było dziewięć set i pięćdziesiąt i sześć: ci wszyscy mężowie byli książętami rodzajów według domów ojców swoich.
10 Ní ti àwọn àlùfáà: Jedaiah; Jehoiaribi; Jakini;
Z kapłanów zasię: Jedejasz, i Jechojaryk, i Jachyn,
11 Asariah ọmọ Hilkiah, ọmọ Meṣullamu, ọmọ Sadoku, ọmọ Meraioti, ọmọ Ahitubu, olórí tí ó ń bojútó ilé Ọlọ́run;
I Azaryjasz, syn Helkijasza, syna Mesullamowego, syna Sadokowego, syna Merajatowego, syna Achytobowego, był książęciam domu Bożego.
12 Adaiah ọmọ Jerohamu, ọmọ Paṣuri, ọmọ Malkiah; àti Masai ọmọ Adieli, ọmọ Jahisera, ọmọ Meṣullamu ọmọ Meṣilemiti, ọmọ Immeri.
I Adajasz, syn Jerohama, syna Fassurowego, syna Melchyjaszowego, i Maasaj, syn Adyjela, syna Jechserowego, syna Mesulla, owego, syna Mesullemitowego, syna Immerowego.
13 Àwọn àlùfáà, tí wọ́n jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé, tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀sán ó dín méjì. Wọ́n jẹ́ alágbára ọkùnrin, tí wọ́n lè dúró fún iṣẹ́ ìránṣẹ́ nínú ilé Ọlọ́run.
A braci ich książęt według domów ojców ich było tysiąc i siedm set i sześćdziesiąt, mążów dużych ku sprawowaniu posługi w domu Bożym.
14 Ní ti àwọn ará Lefi: Ṣemaiah ọmọ Haṣubu, ọmọ Asrikamu, ọmọ Haṣabiah ará Merari;
A z Lewitów: Semejasz, syn Hassuba, syna Asrykamowego, syna Hasabijaszowego, z synów Merarego;
15 Bakibakari, Hereṣi, Galali àti Mattaniah, ọmọ Mika, ọmọ Sikri, ọmọ Asafu;
I Bakkabar, Cheres, i Galal, i Matanijasz, syn Michy, syna Zychrego, syna Asafowego;
16 Obadiah ọmọ Ṣemaiah, ọmọ Galali, ọmọ Jedutuni; àti Berekiah ọmọ Asa, ọmọ Elkana, tí ó ń gbé nínú àwọn ìlú àwọn ará Netofa.
Obadyjasz też, syn Semahajasza, syna Galalowego, syna Jedytunowego, i Barachyjasz, syn Asy, syna Elkanowego, który mieszkał we wsiach Netofatyckich.
17 Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà: Ṣallumu, Akkubu, Talmoni, Ahimani àti arákùnrin wọn, Ṣalumu olóyè wọn,
A odźwierni: Sallum, i Akkub, i Talmon, i Ahyman, i nracia ich; Sallum książę między nimi.
18 ti wà ní ipò ìdúró ní ẹnu-ọ̀nà ọba ní apá ìhà ìlà-oòrùn títí di àkókò yí. Wọ̀nyí ni àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà tí ó jẹ́ ti ìpàgọ́ àwọn ará Lefi.
Który aż dotąd w bramie królewskiej stawał na wschód słońca; ci byli odźwiernymi według pocztów synów Lewiego.
19 Ṣallumu ọmọ Kore ọmọ Ebiasafi, ọmọ Kora, àti àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀. Láti ìdílé rẹ̀ (àwọn ará Korati) ni ó dúró fún ṣíṣọ́ ìloro ẹnu-ọ̀nà àgọ́ gẹ́gẹ́ bí baba wọn ti ń dúró fún ṣíṣọ́ àbáwọlé ibùgbé Olúwa.
Ale Sallum, syn Korego, syna Abijazafowego, syna Korego, i bracia jego z domu ojca jego, Korytczycy byli ku odprawowaniu posługi, stróżami progów namiotu; a ojcowie ich byli nad obozem Pańskim stróżami wejścia.
20 Ní ìgbà àkọ́kọ́ Finehasi ọmọ Eleasari jẹ́ olórí fún àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà, Olúwa sì wà pẹ̀lú rẹ̀.
A Finees syn Eleazarowy, był książęciem nad nimi, a Pan był z nimi.
21 Sekariah, ọmọ Meṣelemiah jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ní àbáwọlé sí àgọ́ ibi ìpàdé.
Zacharyjasz zasię, syn Mesellemijaszowy, był odźwiernym drzwi u namiotu zgromadzenia.
22 Gbogbo rẹ̀ lápapọ̀, àwọn tí a yàn láti jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ní àwọn ìloro jẹ́ igba ó lé méjìlá. A ka àwọn wọ̀nyí nípa ìdílé ní ìletò wọn. Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ni a ti yàn sí ipò láti ọ̀dọ̀ Dafidi àti Samuẹli, aríran, nítorí òtítọ́ wọn.
Cić wszyscy są obrani za odźwiernych do drzwi, dwieście osób i dwanaście: ci we wsiach swych policzeni są, których postanowił Dawid i Samuel widzący, dla wierności ich,
23 Àwọn àti àwọn ọmọ wọn ni ó wà fún ṣíṣọ́ ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa ilé tí a pè ní àgọ́.
Aby oni i synowie ich byli we drzwiach domu Pańskiego, w domu namiotu na straży.
24 Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà wà ní igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin: ìlà-oòrùn, ìwọ̀-oòrùn àríwá àti gúúsù.
I byli odźwierni po czterech stronach, na wschód, na zachód, na północy, i na południe.
25 Àwọn arákùnrin wọn ní àwọn ìletò wọn ní láti wá ní àkókò dé àkókò láti pín iṣẹ́ ìsìn wọn fún àkókò ọjọ́ méje.
Bracia zasię ich byli we wsiach swych, przychodząc każdego siódmego dnia, od czasu aż do czasu odmieniając się z nimi.
26 Ṣùgbọ́n àwọn olórí alábojútó ẹnu-ọ̀nà mẹ́rẹ̀ẹ̀rin tí wọ́n jẹ́ ará Lefi ni a yàn fún àwọn iyàrá àti àwọn àpótí ìṣúra ní ilé Ọlọ́run.
Albowiem pod sprawą tych czterech przedniejszych odźwiernych byli Lewitowie, a byli przełożeni nad gmachami i nad skarbami domu Bożego;
27 Wọ́n á lo gbogbo òru ní dídúró yí ilé Ọlọ́run ká, nítorí wọ́n ní láti ṣọ́ ọ, wọ́n sì ní àṣẹ sí kọ́kọ́rọ́ fún ṣíṣí i ní àràárọ̀.
A około domu Bożego nocowali, gdyż im należała straż jego; a oni go na każdy poranek otwierali.
28 Díẹ̀ wà ní ìdí ohun èlò tí à ń lò fún ìsìn ilé Ọlọ́run; wọn a máa kà á nígbà tí wọ́n gbé e wọlé àti nígbà tí a kó wọn jáde.
A z nich niektórzy byli nad naczyniem ku posługiwaniu; albowiem pod liczbą wnosili je, i pod liczbą wynosili je.
29 Àwọn mìíràn ni a yàn láti bojútó ohun èlò àti gbogbo ohun èlò ilé tí a yà sọ́tọ̀ fún Ọlọ́run, àti ìyẹ̀fun àti ọtí èso àjàrà àti òróró náà, tùràrí àti tùràrí olóòórùn dídùn.
Niektózry zasię z nich byli postanowieni nad innem naczyniem, i nad wszystkiem naczyniem świątnicy, i nad mąką pszenną i winem, i oliwą, i kadzidłem, i nad rzeczami wonnemi.
30 Ṣùgbọ́n díẹ̀ nínú àwọn àlùfáà ni ó ń bojútó pípò tùràrí olóòórùn dídùn papọ̀.
A niektórzy z synów kapłańskich sprawowali maści z rzeczy wonnych.
31 Ará Lefi tí a sọ ní Mattitiah àkọ́bí ọmọkùnrin Ṣallumu ará Kora ni a yàn, tí ń ṣe alábojútó ohun tí a dín.
Matatyjasz też z Lewitów, pierworodny Salluma Korytczyka, był przełożony nad rzeczami, które w panwiach smażono.
32 Àti nínú àwọn arákùnrin wọn, nínú àwọn ọmọ Kohati tó ń ṣe ìtọ́jú àkàrà ìfihàn, láti máa pèsè rẹ̀ ní ọjọọjọ́ ìsinmi.
A z synów Kaatowych z braci ich, byli niektórzy przełożonymi nad chlebami pokładnemi, aby je gotowali na każdy sabat.
33 Àwọn tí wọ́n jẹ́ ọkùnrin, olórí àwọn ìdílé Lefi dúró nínú àgọ́ ilé Olúwa, wọn kò sì ṣe lára iṣẹ́ ìsìn yòókù nítorí wọ́n ń ṣe iṣẹ́ náà lọ́sàn, lóru.
A z tych byli śpiewacy, przedniejsi z domów ojcowskich, między Lewitami mieszkający w gmachach, od inszych prac wolni; bo we dnie i w nocy powinności swej pilnować musieli.
34 Gbogbo wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn Lefi, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe kọ lẹ́sẹẹsẹ sínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
Ci przedniejsi z domów ojcowskich między Lewitami, według narodów swych przedniejsi; ci mieszkali w Jeruzalemie.
35 Jeieli baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Orúkọ ìyàwó rẹ̀ a máa jẹ́ Maaka,
A w Gabaonie mieszkali ojciec Gabaończyków Jehyjel, a imię żony jego Maacha;
36 pẹ̀lú àkọ́bí ọmọkùnrin rẹ̀ jẹ́ Abdoni, tí wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu.
A syn jego pierworodny Abdon, po nim Sur, i Cys, i Baal, i Neer, i Nadab,
37 Gedori, Ahio, Sekariah àti Mikiloti.
I Giedeor, i Achyjo, i Zacharyjasz, i Michlot;
38 Mikiloti jẹ́ baba Ṣimeamu, àwọn náà ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
(A Michlot spłodził Symmama) a ci także przweciw braci swych mieszkali w Jeruzalemie z braćmi swymi.
39 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba a Saulu, àti Saulu baba a Jonatani, àti Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
A Neer spłodził Cysa, a Cys spłodził Saula, a Saul spłodził Jonatana, i Melchisuego, i Abidanaba, i Esbaala.
40 Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali, tí ó jẹ́ baba Mika.
A syn Jonatana Merybbaal; a Merybbaal spłodził Michasa.
41 Àwọn ọmọ Mika: Pitoni. Meleki, Tarea àti Ahasi.
Synowie zaś Michasowi: Fiton, i Melech, i Tarea, i Achaz.
42 Ahasi jẹ́ baba Jada, Jada jẹ́ baba Alemeti, Asmafeti, Simri, sì Simri jẹ́ baba Mosa.
A Achaz spłodził Jarę; a Jara spłodził Alemeta, i Asmaweta, i Zynrego; a Zymry spłodził Mosę.
43 Mosa jẹ́ baba Binea; Refaiah jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
A Mosa spłodził Binę; a Refajasz syn jego, Elasa syn jego, Asel syn jego.
44 Aseli ní ọmọ mẹ́fà, pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli Ṣeariah, Obadiah àti Hanani, gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
A Asel miał sześć synów; a teć imiona ich: Asrykam, i Bochru, i Ismael, i Searyjasz, i Obadyjasz, i Hanan. Cić są synowie Aselowi.

< 1 Chronicles 9 >