< 1 Chronicles 9 >

1 Gbogbo Israẹli ni a kọ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ àwọn baba ńlá nínú ìwé àwọn ọba Israẹli. Àwọn ènìyàn Juda ni a kó ní ìgbèkùn lọ sí Babeli nítorí àìṣòótọ́ wọn.
Az egész Izráel megszámláltatván nemzetségeik szerint, beirattak az Izráel és Júda királyainak könyvébe, a kik gonoszságukért Babilóniába vitetének.
2 Nísinsin yìí, àwọn tí ó kọ́kọ́ tún tẹ̀dó lórí ohun ìní wọn ní ìlú wọn ni díẹ̀ nínú àwọn ọmọ Israẹli, àwọn àlùfáà, àwọn ará Lefi àti àwọn ìránṣẹ́ ilé Olúwa.
A legelső lakosok az ő jószágaikon s városaikban, ezek: Izráeliták, papok, Léviták és Nétineusok.
3 Àwọn tí ó wá láti Juda láti Benjamini àti láti Efraimu àti Manase tí ó ń gbé ní Jerusalẹmu jẹ́:
Mert Jeruzsálemben laktak a Júda fiai közül s Benjámin fiai közül, Efraim és Manasse fiai közül valók:
4 Uttai ọmọ Ammihudu, ọmọ Omri, ọmọ Imri, ọmọ Bani, ìran ọmọ Peresi ọmọ Juda.
Utái, Ammihud fia, ki Omri fia, ki Imri fia, ki Báni fia, a Pérecz fiai közül való, ki Júda fia vala.
5 Àti nínú ará Ṣilo: Asaiah àkọ́bí àti àwọn ọmọ rẹ̀.
A Silóniták közül, Asája, ki elsőszülött vala s ennek fiai.
6 Ní ti ará Sera: Jeueli. Àwọn ènìyàn láti Juda sì jẹ́ ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́wàá.
A Zérah fiai közül: Jéuel és az ő atyjafiai, hatszázkilenczvenen.
7 Àti nínú àwọn ọmọ Benjamini ni: Sallu ọmọ Meṣullamu, ọmọ Hodafiah; ọmọ Hasenuah;
A Benjámin fiai közül: Sallu, Mésullám fia, ki Hodávia fia, ki Hasénua fia.
8 Ibinaiah ọmọ Jerohamu; Ela ọmọ Ussi, ọmọ Mikri; àti Meṣullamu ọmọ Ṣefatia; ọmọ Reueli, ọmọ Ibinijah.
Ibnéja, Jérohám fia, és Ela, Uzzi fia, ki Mikri fia, és Mésullám, Séfátja fia, ki Reuel fia, ki Ibnija fia vala.
9 Àwọn ènìyàn láti Benjamini gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe kọ ọ́ nínú ìran wọn nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó dín mẹ́rìnlélógójì. Gbogbo àwọn ọkùnrin yí jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé.
Testvéreik, nemzetségeik szerint, kilenczszázötvenhatan valának; ezek mind családfők voltak az ő atyjok háznépe szerint.
10 Ní ti àwọn àlùfáà: Jedaiah; Jehoiaribi; Jakini;
A papok közül is: Jedája, Jéhojárib és Jákin.
11 Asariah ọmọ Hilkiah, ọmọ Meṣullamu, ọmọ Sadoku, ọmọ Meraioti, ọmọ Ahitubu, olórí tí ó ń bojútó ilé Ọlọ́run;
Azária, Hilkia fia, ki Mésullám fia, ki Sádók fia, ki Mérajót fia, ki Ahitubnak, az Isten háza főgondviselőjének fia vala.
12 Adaiah ọmọ Jerohamu, ọmọ Paṣuri, ọmọ Malkiah; àti Masai ọmọ Adieli, ọmọ Jahisera, ọmọ Meṣullamu ọmọ Meṣilemiti, ọmọ Immeri.
És Adája Jérohám fia, ki Pashúr fia, ki Málkija fia; Maasai, Adiel fia, ki Jahzéra fia, ki Mésullám fia, ki Mésillémit fia, ki Immer fia.
13 Àwọn àlùfáà, tí wọ́n jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé, tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀sán ó dín méjì. Wọ́n jẹ́ alágbára ọkùnrin, tí wọ́n lè dúró fún iṣẹ́ ìránṣẹ́ nínú ilé Ọlọ́run.
Ezeknek atyjokfiai az ő családjaiknak fejei, ezerhétszázhatvanan valának, buzgók az Isten háza dolgának munkájában.
14 Ní ti àwọn ará Lefi: Ṣemaiah ọmọ Haṣubu, ọmọ Asrikamu, ọmọ Haṣabiah ará Merari;
A Léviták közül Semája, Hásub fia, ki Azrikám fia, ki Hasábia fia, a Mérári fiai közül.
15 Bakibakari, Hereṣi, Galali àti Mattaniah, ọmọ Mika, ọmọ Sikri, ọmọ Asafu;
Bakbakkár, Héres és Galál, és Mattánia, a Mika fia, ki Zikri fia, ki Asáf fia vala.
16 Obadiah ọmọ Ṣemaiah, ọmọ Galali, ọmọ Jedutuni; àti Berekiah ọmọ Asa, ọmọ Elkana, tí ó ń gbé nínú àwọn ìlú àwọn ará Netofa.
Obádia, a Semája fia, Galál fia, ki Jédutun fia, és Bérékia, Asa fia, ki Elkána fia, a ki Nétofáti faluiban lakik vala.
17 Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà: Ṣallumu, Akkubu, Talmoni, Ahimani àti arákùnrin wọn, Ṣalumu olóyè wọn,
És az ajtónállók: Sallum, Akkúb, Talmon, Ahimán és ezek testvérei; Sallum pedig fő vala.
18 ti wà ní ipò ìdúró ní ẹnu-ọ̀nà ọba ní apá ìhà ìlà-oòrùn títí di àkókò yí. Wọ̀nyí ni àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà tí ó jẹ́ ti ìpàgọ́ àwọn ará Lefi.
(És ennek mindez ideig a királykapun van helye napkelet felől.) Ezek az ajtónállók a Léviták rendje szerint.
19 Ṣallumu ọmọ Kore ọmọ Ebiasafi, ọmọ Kora, àti àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀. Láti ìdílé rẹ̀ (àwọn ará Korati) ni ó dúró fún ṣíṣọ́ ìloro ẹnu-ọ̀nà àgọ́ gẹ́gẹ́ bí baba wọn ti ń dúró fún ṣíṣọ́ àbáwọlé ibùgbé Olúwa.
Sallum pedig a Kóré fia, ki Ebiásáf fia, ki Kórákh fia, és ennek rokonságai a Kórakhiták családjából a szolgálat munkájában a hajlék ajtajának őrizői valának, mint az ő atyáik az Úr seregében őrizték vala a bejáratot,
20 Ní ìgbà àkọ́kọ́ Finehasi ọmọ Eleasari jẹ́ olórí fún àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà, Olúwa sì wà pẹ̀lú rẹ̀.
Mikor Fineás, az Eleázár fia volt egykor az ő előljárójok, kivel az Úr vala.
21 Sekariah, ọmọ Meṣelemiah jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ní àbáwọlé sí àgọ́ ibi ìpàdé.
Zakariás, a Meselémia fia, a gyülekezet sátorába való bejárat őrizője.
22 Gbogbo rẹ̀ lápapọ̀, àwọn tí a yàn láti jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ní àwọn ìloro jẹ́ igba ó lé méjìlá. A ka àwọn wọ̀nyí nípa ìdílé ní ìletò wọn. Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ni a ti yàn sí ipò láti ọ̀dọ̀ Dafidi àti Samuẹli, aríran, nítorí òtítọ́ wọn.
Ezek mind választott ajtónállók voltak, kétszáztizenketten; kik az ő faluikban, nemzetségök szerint, megszámláltattak volt; kiket Dávid rendelt és Sámuel próféta az ő tisztökbe.
23 Àwọn àti àwọn ọmọ wọn ni ó wà fún ṣíṣọ́ ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa ilé tí a pè ní àgọ́.
Ők és fiaik őrizik vala renddel az Úr házának, a sátornak kapuit.
24 Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà wà ní igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin: ìlà-oòrùn, ìwọ̀-oòrùn àríwá àti gúúsù.
Négyfelé valának az őrizők: napkeletre, napnyugotra, északra és délre.
25 Àwọn arákùnrin wọn ní àwọn ìletò wọn ní láti wá ní àkókò dé àkókò láti pín iṣẹ́ ìsìn wọn fún àkókò ọjọ́ méje.
És ezeknek atyjokfiai az ő faluikban valának, de minden hetednap amazokhoz felmenének Jeruzsálembe bizonyos ideig.
26 Ṣùgbọ́n àwọn olórí alábojútó ẹnu-ọ̀nà mẹ́rẹ̀ẹ̀rin tí wọ́n jẹ́ ará Lefi ni a yàn fún àwọn iyàrá àti àwọn àpótí ìṣúra ní ilé Ọlọ́run.
De a kapunállók négy főemberének állandó megbizatásuk volt. Ezek a Léviták őrizik vala a kamarákat és az Isten házának kincseit.
27 Wọ́n á lo gbogbo òru ní dídúró yí ilé Ọlọ́run ká, nítorí wọ́n ní láti ṣọ́ ọ, wọ́n sì ní àṣẹ sí kọ́kọ́rọ́ fún ṣíṣí i ní àràárọ̀.
És az Úrnak háza körül hálnak vala, mivelhogy az őrzés az ő tisztök volt, és minden reggel ők nyitják vala meg az ajtókat.
28 Díẹ̀ wà ní ìdí ohun èlò tí à ń lò fún ìsìn ilé Ọlọ́run; wọn a máa kà á nígbà tí wọ́n gbé e wọlé àti nígbà tí a kó wọn jáde.
És ő közülök némelyek a szolgálati edényekre viselnek vala gondot; mert mind a kivitelnél, mind a visszavitelnél számon veszik vala azokat.
29 Àwọn mìíràn ni a yàn láti bojútó ohun èlò àti gbogbo ohun èlò ilé tí a yà sọ́tọ̀ fún Ọlọ́run, àti ìyẹ̀fun àti ọtí èso àjàrà àti òróró náà, tùràrí àti tùràrí olóòórùn dídùn.
Ugyanazok közül választattak vala némelyek másféle edénynek, a szenthely minden eszközeinek, a lisztnek, bornak, olajnak, tömjénnek és fűszereknek gondviselésére.
30 Ṣùgbọ́n díẹ̀ nínú àwọn àlùfáà ni ó ń bojútó pípò tùràrí olóòórùn dídùn papọ̀.
A papok fiai közül valók csinálják vala fűszerekből a drágakenetet is.
31 Ará Lefi tí a sọ ní Mattitiah àkọ́bí ọmọkùnrin Ṣallumu ará Kora ni a yàn, tí ń ṣe alábojútó ohun tí a dín.
Továbbá Mattitja, a Léviták közül való (ki elsőszülötte a Kórakhiták közül való Sallumnak), a serpenyőkre visel vala gondot.
32 Àti nínú àwọn arákùnrin wọn, nínú àwọn ọmọ Kohati tó ń ṣe ìtọ́jú àkàrà ìfihàn, láti máa pèsè rẹ̀ ní ọjọọjọ́ ìsinmi.
A Kéhátiták fiai és azok atyjokfiai közül rendeltettek volt a szent kenyérnek gondviselésére, hogy minden szombaton megkészítsék azt.
33 Àwọn tí wọ́n jẹ́ ọkùnrin, olórí àwọn ìdílé Lefi dúró nínú àgọ́ ilé Olúwa, wọn kò sì ṣe lára iṣẹ́ ìsìn yòókù nítorí wọ́n ń ṣe iṣẹ́ náà lọ́sàn, lóru.
Ezek közül valók valának az éneklők is, a Léviták közül a családfők, a kik szabadosok valának egyéb tiszttől az ő kamarájokban; mert éjjel és nappal szolgálattal tartoznak vala.
34 Gbogbo wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn Lefi, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe kọ lẹ́sẹẹsẹ sínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
Ezek a Léviták között családfők nemzetségök szerint, főemberek, és ezek Jeruzsálemben laktak.
35 Jeieli baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Orúkọ ìyàwó rẹ̀ a máa jẹ́ Maaka,
Gibeonban pedig laktak a Gibeon atyja, Jéhiel, és az ő feleségének neve Maaka.
36 pẹ̀lú àkọ́bí ọmọkùnrin rẹ̀ jẹ́ Abdoni, tí wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu.
Az ő elsőszülött fia Abdon, azután Súr, Kis, Baál, Nér és Nádáb.
37 Gedori, Ahio, Sekariah àti Mikiloti.
Gedor, Ahió, Zékária és Miklót.
38 Mikiloti jẹ́ baba Ṣimeamu, àwọn náà ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
Miklót pedig nemzé Simámot. Ezek is az ő atyjokfiai átellenében laktak Jeruzsálemben az ő testvéreikkel.
39 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba a Saulu, àti Saulu baba a Jonatani, àti Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
Nér nemzé Kist, Kis nemzé Sault, Saul pedig nemzé Jonathánt, Málkisuát, Abinádábot és Esbaált.
40 Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali, tí ó jẹ́ baba Mika.
Jonathán fia Méribbaál; és Méribbaál nemzé Mikát.
41 Àwọn ọmọ Mika: Pitoni. Meleki, Tarea àti Ahasi.
Mika fiai: Piton, Mélek és Táréa.
42 Ahasi jẹ́ baba Jada, Jada jẹ́ baba Alemeti, Asmafeti, Simri, sì Simri jẹ́ baba Mosa.
Akház pedig nemzé Jahrát, Jahra nemzé Alémetet, Azmávetet, Zimrit, Zimri pedig nemzé Mósát.
43 Mosa jẹ́ baba Binea; Refaiah jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
Mósa nemzé Bineát, ennek fia Réfája, ennek fia Elása, ennek fia Ásel.
44 Aseli ní ọmọ mẹ́fà, pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli Ṣeariah, Obadiah àti Hanani, gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
Áselnek hat fia volt, kiknek neveik: Azrikám, Bókru, Ismáel, Seárja, Obádia és Hanán; ezek Ásel fiai.

< 1 Chronicles 9 >