< 1 Chronicles 8 >

1 Benjamini jẹ́ baba: Bela àkọ́bí rẹ̀, Aṣbeli ọmọkùnrin ni ẹ̀ẹ̀kejì, Ahara ẹ̀ẹ̀kẹ́ta,
BENJAMÍN engendró á Bela su primogénito, Asbel el segundo, Ara el tercero,
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
Noha el cuarto, y Rapha el quinto.
3 Àwọn ọmọ Bela ni, Adari, Gera, Abihudi,
Y los hijos de Bela fueron Addar, Gera, Abiud,
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
Abisua, Naamán, Ahoa,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
Y Gera, Sephuphim, y Huram.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
Y estos son los hijos de Ehud, estos las cabezas de padres que habitaron en Gabaa, y fueron trasportados á Manahath:
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
[Es á saber]: Naamán, Achîas, y Gera: éste los trasportó, y engendró á Uzza, y á Ahihud.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
Y Saharaim engendró hijos en la provincia de Moab, después que dejó á Husim y á Baara que eran sus mujeres.
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
Engendró pues de Chôdes su mujer, á Jobab, Sibias, Mesa, Malchâm,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
Jeus, Sochîas, y Mirma. Estos son sus hijos, cabezas de familias.
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
Mas de Husim engendró á Abitob, y á Elphaal.
12 Àwọn ọmọ Elipali: Eberi, Miṣamu, Ṣemedu (ẹni tí ó kọ́ Ono àti Lodi pẹ̀lú àwọn ìletò àyíká rẹ̀.)
Y los hijos de Elphaal: Heber, Misam, y Semeb, (el cual edificó á Ono, y á Loth con sus aldeas, )
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
Berías también, y Sema, que fueron las cabezas de las familias de los moradores de Ajalón, los cuales echaron á los moradores de Gath;
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
Y Ahío, Sasac, Jeremoth;
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
Zebadías, Arad, Heder;
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
Michâel, Ispha, y Joa, hijos de Berías;
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
Y Zebadías, Mesullam, Hizchî, Heber;
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
Ismari, Izlia, y Jobab, hijos de Elphaal.
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
Y Jacim, Zichri, Zabdi;
20 Elienai, Siletai, Elieli,
Elioenai, Silithai, Eliel;
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
Adaías, Baraías, y Simrath, hijos de Simi;
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
E Isphán, Heber, Eliel;
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
Adón, Zichri, Hanán;
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
Hananía, Belam, Anathothías;
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
Iphdaías, y Peniel, hijos de Sasac;
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
Y Samseri, Seharías, Atalía;
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
Jaarsías, Elías, Zichri, hijos de Jeroham.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
Estos fueron jefes principales de familias por sus linajes, y habitaron en Jerusalem.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Ìyàwó o rẹ̀ a má jẹ́ Maaka,
Y en Gabaón habitaron Abiga-baón, la mujer del cual se llamó Maachâ:
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
Y su hijo primogénito, Abdón, luego Sur, Chîs, Baal, Nadab,
31 Gedori Ahio, Sekeri
Gedor, Ahíe, y Zechêr.
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
Y Micloth engendró á Simea. Estos también habitaron con sus hermanos en Jerusalem, enfrente de ellos.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
Y Ner engendró á Cis, y Cis engendró á Saúl, y Saúl engendró á Jonathán, Malchî-súa, Abinadab, y Esbaal.
34 Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali tí ó jẹ́ baba Mika.
Hijo de Jonathán fué Merib-baal, y Merib-baal engendró á Michâ.
35 Àwọn ọmọ Mika: Pitoni, Meleki, Tarea, àti Ahasi.
Los hijos de Michâ: Phitón, Melech, Thaarea y Ahaz.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
Y Ahaz engendró á Joadda; y Joadda engendró á Elemeth, y á Azmaveth, y á Zimri; y Zimri engendró á Mosa;
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
Y Mosa engendró á Bina, hijo del cual fué Rapha, hijo del cual [fué] Elasa, cuyo hijo [fué] Asel.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli, Ṣeariah, Obadiah àti Hanani. Gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
Y los hijos de Asel fueron seis, cuyos nombres son Azricam, Bochru, Ismael, Searías, Obadías, y Hanán: todos estos fueron hijos de Asel.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki: Ulamu àkọ́bí rẹ̀, Jeuṣi ọmọkùnrin ẹ̀ẹ̀kejì àti Elifeleti ẹ̀ẹ̀kẹ́ta.
Y los hijos de Esec su hermano: Ulam su primogénito, Jehus el segundo, Elipheleth el tercero.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀. Gbogbo wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ìran ọmọ Benjamini.
Y fueron los hijos de Ulam hombres valientes y vigorosos, flecheros diestros, los cuales tuvieron muchos hijos y nietos, ciento y cincuenta. Todos estos fueron de los hijos de Benjamín.

< 1 Chronicles 8 >