< 1 Chronicles 1 >

1 Adamu, Seti, Enoṣi,
ADAM, Seth, Enos,
2 Kenani, Mahalaleli, Jaredi,
Cainán, Mahalaleel, Jared,
3 Enoku, Metusela, Lameki, Noa.
Enoch, Mathusalem, Lamech,
4 Àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti.
Noé, Sem, Châm, y Japhet.
5 Àwọn ọmọ Jafeti ni: Gomeri, Magogu, Madai; Jafani, Tubali, Meṣeki àti Tirasi.
Los hijos de Japhet: Gomer, Magog, Dadai, Javán, Tubal, Mesec, y Thiras.
6 Àwọn ọmọ Gomeri ni: Aṣkenasi, Rifati àti Togarma.
Los hijos de Gomer: Askenaz, Riphath, y Thogorma.
7 Àwọn ọmọ Jafani ni: Eliṣa, Tarṣiṣi, Kittimu, àti Dodanimu.
Los hijos de Javán: Elisa, Tharsis, Chîthim, y Dodanim.
8 Àwọn ọmọ Hamu ni: Kuṣi, Ejibiti, Puti, àti Kenaani.
Los hijos de Châm: Chûs, Misraim, Phuth, y Canaán.
9 Àwọn ọmọ Kuṣi ni: Seba, Hafila, Sabta, Raama, àti Sabteka. Àwọn ọmọ Raama: Ṣeba àti Dedani.
Los hijos de Chûs: Seba, Havila, Sabtha, Raema, y Sabtechâ. Y los hijos de Raema: Seba y Dedán.
10 Kuṣi sì bí Nimrodu ẹni tí ó di alágbára jagunjagun ní ayé.
Chûs engendró á Nimrod: éste comenzó á ser poderoso en la tierra.
11 Ejibiti sì bí Ludimu, Anamimu, Lehabimu, Naftuhimu,
Misram engendró á Ludim, Ananim, Laabim, Nephtuim,
12 Patrusimu, Kasluhimu (láti ọ̀dọ̀ ẹni tí àwọn ará Filistini ti wá) àti àwọn ará Kaftorimu.
Phetrusim y Casluim: de éstos salieron los Filisteos, y los Caphtoreos.
13 Kenaani sì bí Sidoni àkọ́bí rẹ̀, àti Heti,
Canaán engendró á Sidón, su primogénito;
14 àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi,
Y al Hetheo, y al Jebuseo, y al Amorrheo, y al Gergeseo;
15 àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini,
Y al Heveo, y al Araceo, y al Sineo;
16 àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Semari, àti àwọn ará Hamati.
Al Aradeo, y al Samareo, y al Hamatheo.
17 Àwọn ọmọ Ṣemu ni: Elamu, Aṣuri, Arfakṣadi, Ludi àti Aramu. Àwọn ọmọ Aramu: Usi, Huli, Geteri, àti Meṣeki.
Los hijos de Sem: Elam, Assur, Arphaxad, Lud, Aram, Hus, Hul, Gether, y Mesec.
18 Arfakṣadi sì bí Ṣela, Ṣela sì bí Eberi.
Arphaxad engendró á Sela, y Sela engendró á Heber.
19 Eberi sì bí ọmọ méjì: ọ̀kan ń jẹ́ Pelegi, nítorí ní ìgbà ọjọ́ rẹ̀ ni ilẹ̀ ya; orúkọ arákùnrin rẹ̀ ni Joktani.
Y á Heber nacieron dos hijos: el nombre del uno fué Peleg, por cuanto en sus días fué dividida la tierra; y el nombre de su hermano fué Joctán.
20 Joktani sì bí Almodadi, Ṣelefi, Hasarmafeti, Jera.
Y Joctán engendró á Elmodad, Seleph, Asarmaveth, y Jera,
21 Hadoramu, Usali, Dikla,
A Adoram también, á Uzal, Dicla,
22 Ebali, Abimaeli, Ṣeba.
Hebal, Abimael, Seba,
23 Ofiri, Hafila, àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.
Ophir, Havila, y Jobab: todos hijos de Joctán.
24 Ṣemu, Arfakṣadi, Ṣela,
Sem, Arphaxad, Sela,
25 Eberi, Pelegi. Reu,
Heber, Peleg, Reu,
26 Serugu, Nahori, Tẹra,
Serug, Nachôr, Thare,
27 àti Abramu (tí ń ṣe Abrahamu).
Y Abram, el cual es Abraham.
28 Àwọn ọmọ Abrahamu: Isaaki àti Iṣmaeli.
Los hijos de Abraham: Isaac é Ismael.
29 Èyí ni àwọn ọmọ náà: Nebaioti àkọ́bí Iṣmaeli: Kedari, Adbeeli, Mibsamu,
Y estas son sus descendencias: el primogénito de Ismael, Nabajoth; después Cedar, Adbeel, Misam,
30 Miṣima, Duma, Massa, Hadadi, Tema,
Misma, Duma, Maasa, Hadad, Thema, Jetur, Naphis, y Cedma. Estos son los hijos de Ismael.
31 Jeturi, Nafiṣi, àti Kedema. Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Iṣmaeli.
Y Cethura, concubina de Abraham, parió á Zimram, Jocsán, Medán, Madián, Isbac, y á Súa.
32 Àwọn ọmọ Ketura, obìnrin Abrahamu: Simrani, Jokṣani Medani, Midiani Iṣbaki àti Ṣua. Àwọn ọmọ Jokṣani: Ṣeba àti Dedani.
Los hijos de Jobsán: Seba y Dedán.
33 Àwọn ọmọ Midiani: Efani, Eferi, Hanoku, Abida àti Eldaa. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ìran Ketura.
Los hijos de Madián: Epha, Epher, Henoch, Abida, y Eldaa; todos estos fueron hijos de Cethura.
34 Abrahamu sì jẹ́ baba Isaaki. Àwọn ọmọ Isaaki: Esau àti Israẹli.
Y Abraham engendró á Isaac: y los hijos de Isaac [fueron] Esaú é Israel.
35 Àwọn ọmọ Esau: Elifasi, Reueli, Jeuṣi, Jalamu, àti Kora.
Los hijos de Esaú: Eliphas, Rehuel, Jeus, Jalam, y Cora.
36 Àwọn ọmọ Elifasi: Temani, Omari, Sefi, Gatamu àti Kenasi; láti Timna: Amaleki.
Los hijos de Eliphas: Themán, Omar, Sephi, Hatham, Chênas, Timna, y Amalec.
37 Àwọn ọmọ Reueli: Nahati, Sera, Ṣamma àti Missa.
Los hijos de Rehuel: Nahath, Zera, Samma, y Mizza.
38 Àwọn ọmọ Seiri: Lotani, Ṣobali, Sibeoni, Ana, Diṣoni, Eseri àti Diṣani.
Los hijos de Seir: Lotán, Sobal, Sibeón, Ana, Disón, Eser, y Disán.
39 Àwọn ọmọ Lotani: Hori àti Homamu: Timna sì ni arábìnrin Lotani.
Los hijos de Lotán: Hori, y Homam: y Timna fué hermana de Lotán.
40 Àwọn ọmọ Ṣobali: Afiani, Manahati, Ebali, Ṣefo àti Onamu. Àwọn ọmọ Sibeoni: Aiah àti Ana.
Los hijos de Sobal: Alian, Manahach, Ebal, Sephi y Oman. Los hijos de Sibehom: Aia y Ana.
41 Àwọn ọmọ Ana: Diṣoni. Àwọn ọmọ Diṣoni: Hemdani, Eṣbani, Itrani, àti Kerani.
Disón fué hijo de Ana: y los hijos de Disón; Hamrán, Hesbán, Ithran y Chêrán.
42 Àwọn ọmọ Eseri: Bilhani, Saafani àti Akani. Àwọn ọmọ Diṣani: Usi àti Arani.
Los hijos de Eser: Bilham, Zaaván, y Jaacán. Los hijos de Disán: Hus y Arán.
43 Àwọn wọ̀nyí ni ọba tí ó jẹ ní Edomu, kí ó tó di pé ọba kankan jẹ lórí Israẹli: Bela ọmọ Beori, orúkọ ìlú rẹ̀ ni Dinhaba.
Y estos son los reyes que reinaron en la tierra de Edom, antes que reinase rey sobre los hijos de Israel: Belah, hijo de Beor; y el nombre de su ciudad fué Dinaba.
44 Nígbà tí Bela kú, Jobabu ọmọ Sera ti Bosra sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Y muerto Belah, reinó en su lugar Jobab hijo de Zera, de Bosra.
45 Nígbà tí Jobabu kú, Huṣamu láti ilẹ̀ Temani sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Y muerto Jobab, reinó en su lugar Husam, de la tierra de los Themanos.
46 Nígbà tí Huṣamu kú, Hadadi ọmọ Bedadi tí ó kọlu Midiani ní ìgbẹ́ Moabu, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Afiti.
Muerto Husam, reinó en su lugar Adad hijo de Bedad, el cual hirió á Madián en la campaña de Moab: y el nombre de su ciudad fué Avith.
47 Nígbà tí Hadadi sì kú, Samla láti Masreka, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Muerto Adad, reinó en su lugar Samla, de Masreca.
48 Samla sì kú, Saulu ti Rehoboti létí odò sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Muerto también Samla, reinó en su lugar Saúl de Rehoboth, que está junto al río.
49 Nígbà tí Saulu kú, Baali-Hanani, ọmọ Akbori jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Y muerto Saúl, reinó en su lugar Baal-hanán hijo de Achbor.
50 Nígbà tí Baali-Hanani kú, Hadadi ni ó jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Pau; orúkọ ìyàwó sì ni Mehetabeeli ọmọbìnrin Matiredi, ọmọbìnrin Mesahabu.
Y muerto Baal-hanán, reinó en su lugar Adad, el nombre de cuya ciudad fué Pai; y el nombre de su mujer Meetabel, hija de Matred, y ésta de Mezaab.
51 Hadadi sì kú pẹ̀lú. Àwọn baálẹ̀ Edomu ni: baálẹ̀ Timna, baálẹ̀ Alfa, baálẹ̀ Jeteti
Muerto Adad, sucedieron los duques en Edom: el duque Timna, el duque Alia, el duque Jetheth,
52 baálẹ̀ Oholibama, baálẹ̀ Ela, baálẹ̀ Pinoni.
El duque Oholibama, el duque Ela, el duque Phinón,
53 Baálẹ̀ Kenasi, baálẹ̀ Temani, baálẹ̀ Mibsari,
El duque Chênaz, el duque Themán, el duque Mibzar,
54 Magdieli àti Iramu. Àwọn wọ̀nyí ni baálẹ̀ Edomu.
El duque Magdiel, el duque Iram. Estos fueron los duques de Edom.

< 1 Chronicles 1 >